TheCable Fact Check
  • Home
  • Fact Check
  • Fake News
  • Check Am For Wazobia
Reading: Rárá o, owó ilé ìwé àwọn akẹ́kọ̀ọ́ girama tí ìjọba àpapọ̀ kò tíì di N380k
Share
Latest News
FACT CHECK: Video showing ‘bridge collapsing in Nasarawa’ is AI-generated
MISINFO ALERT: Viral video of ‘foreign arms dealer’ in Zamfara is from 2021, says army
Ókwú Badenoch nà ụ́mụ̀ yá ápụ̀ghị̀ ínwétá íkíké ị́bụ ńdị́ Naijiria bụ̀ àsị́
Kemi Badenoch claim sey her children no fit get Nigerian citizenship but she no tok true
Irọ́ ni Kemi Badenoch pa pé òfin kò fààyè gba àwọn ọmọ òhun láti di ọmọ Nàìjíríà
Maganar Kemi Badenoch na cewa ‘ya’yanta ba za su iya samun shaidar zama dan Najeriya ba karya ne
FACT CHECK: Kemi Badenoch’s claim that her children can’t get Nigerian citizenship is false
Naijiria ọ̀ kàgbùrù ńkwékọ́rị́tá àzụ́máhị́á àkụ̀ ọ̀nàtàràchí yá nà US nwèrè n’íhì ḿmáchí visa?
Advertisement
Aa
TheCable Fact CheckTheCable Fact Check
Search
  • Home
  • Fact Check
  • Fake News
  • Check Am For Wazobia
Follow US

Rárá o, owó ilé ìwé àwọn akẹ́kọ̀ọ́ girama tí ìjọba àpapọ̀ kò tíì di N380k

Yemi Michael
By Yemi Michael Published September 1, 2024 4 Min Read
Share

Ọ̀rọ̀ kan lórí ayélujára sọ pé ìjọba àpapọ̀ ti “sọ ilé ẹ̀kọ́ gírámà, èyí tí inú wọn jẹ́ ti ijọba àpapọ̀ di ti aládáni” ní orílẹ̀-èdè Nàìjíríà.

Ẹni tí ó fi ọ̀rọ̀ yìí síta tí a mọ̀ sí Ọlọ́runyẹmí Kẹhinde Patrick, sọ lórí fesibuuku (facebook) pé Ààrẹ Bọla Tinubu “láìyanilẹ́nu” ṣe ìkéde ètò nípa “gbígbé owó orí mìíràn jáde.”

Nínú ọ̀rọ̀ yìí, ẹni yìí sọ pé akẹ́kọ̀ọ́ kọ̀ọ̀kan ní ilé ẹ̀kọ́ gíga tí ìjọba máa san ẹgbẹ̀rún lọ́nà irínwó ó dín ogún náírà fún ọdún kan.

Patrick ṣe ìpín owó náà láti lè jẹ́ kí àwọn ènìyàn mọ ìdí tí ó fi tó iye yìí. Ó ní ẹgbẹ̀rún lọ́nà ọgọ́rùn-ún ó dín mẹ́ta náírà ni owó ilé-ìwé, ẹgbẹ̀rún mẹwa náírà fún owó ibi tí wọ́n máa gbé ní ilé-ìwé, ẹgbẹ̀rún marundinniaadọta náírà fún ìwé kíkà àti ẹgbẹ̀rún mẹ́tàlá náírà fún ìwé tí wọ́n máa kọ nkan sí.

Àwọn owó tí ó kù ni ẹgbẹ̀rún lọ́nà àádọ́ta náírà fún aṣọ ilé-ìwé, ẹgbẹ̀rún mẹwa náírà fún ètò ìpèsè fún òfò, ẹgbẹ̀rún márùn-ún náírà fún àwọn nǹkan tí wọ́n fi máa ń kọ eléyìí, kọ tọun àti ẹgbẹ̀rún mẹwa fún ẹ̀kọ́ tí wọ́n máa ń kọ lẹhìn ìgbà tí ilé ìwé bá lu ago ìlọsílé.

“Nígbà tó jẹ́ ọ̀dọ̀ Tinubu ni ọ̀rọ̀ yìí ti wá, eléyìí kìí ṣe ìròyìn gidi. Tí Tinubu kò bá ṣe èyí ni ìròyìn,” báyìí ni ọ̀rọ̀ tí Patrick kọ ṣe wí.

“Kó má jẹ́ pé ó tún fẹ́ gbé owó orí mìíràn jáde lórí ẹ̀kọ́ gírámà láti lè rí owó tó fi máa ra ọkọ̀ òfuurufú tuntun fún Akpabio àti Abbas, agbẹnusọ fún ilé igbimọ asofin kékeré fún gbogbo “ATILẸYIN” tí wọ́n se fún ara wọn láti ba Nàìjíríà jẹ́.

Ìgbà ọgọ́rin ni àwọn ènìyàn fẹ́ràn ọ̀rọ̀ yìí, ìgbà mẹtadinlọgọrin ni àwọn ènìyàn sọ̀rọ̀ nípa ọ̀rọ̀ yìí. Ìgbà mẹrindinlọgbọn ni àwọn tí wọ́n ń lo ohun ìgbàlódé ibaraẹnise (social media) pín ọ̀rọ̀ yìí.

ÀYẸ̀WÒ Ọ̀RỌ̀ YÌÍ

TheCable, ìwé ìròyìn orí ayélujára ṣe àkíyèsí àwọn àsìkọ̀ àti adirẹsi Ibùgbé  inú ọ̀rọ̀ yìí.

Ní akọkọ, wọ́n si ìkan nínú owó ilé-ìwé kọ. Bí àpẹẹrẹ, lára àwọn àsìkọ yìí ni “school media” tí wọ́n kọ gẹ́gẹ́bí “skool media”.

Láfikún, ẹni yìí sọ pé atẹjade tí òhun fi síta yìí wá láti “office of the director, senior secondary school education operatives” èyí tí ó yẹ kí o jẹ́  “office of the director, senior secondary school department”, èyí tí ó jẹ́ adirẹsi tí ó yẹ.

TheCable tún rí ìyàtọ̀ láàárín ontẹ (signature) lórí atẹjade ẹni yìí àti ontẹ Binta Abdulkadir, olùdarí senior secondary school education.

A tún ríi pé àwọn ilé isẹ ìròyìn tí wọ́n ṣeé gbára lé kò sọ̀rọ̀ nípa ọ̀rọ̀ yìí. Àwọn bloggers nikan ló gbé e jáde.

Ẹka ìjọba àpapọ̀ tó ń rí sí ètò ẹ̀kọ́ sọ pé ọ̀rọ̀ kátíkàti ni ọ̀rọ̀ yìí. Wọ́n ní iye owó tí ó pọ̀ jù tí àwọn ọmọ Federal Unity Colleges (FUCs) san ni ẹgbẹ̀rún ní ọ̀nà ọgọ́rùn-ún náírà, èyí tí ó jẹ́ owó ilé-ìwé fún àwọn akẹ́kọ̀ọ́ tí wọ́n sẹ̀sẹ̀ gbà sí ilé-ìwé. Owó yìí jẹ́ owó aṣọ ilé-ìwé àti owó àwọn nǹkan tí wọ́n máa rà fi kọ ìwé.

Ẹka ìjọba yìí sọ pé ọ̀rọ̀ Patrick yìí máa si àwọn òbí àwọn akẹ́kọ̀ọ́ lọ́nà.

BÍ A ṢE RÍ Ọ̀RỌ̀ YÌÍ ṢÍ

Ọ̀rọ̀ tí Patrick sọ yìí kìí ṣe òótọ́.

TAGGED: Fact check in Yoruba, increment, News in Yorùbá, Unity schools

Please send your feedback, claims to fact check and corrections requests to [email protected]

Yemi Michael September 1, 2024 September 1, 2024
Share this Article
Facebook Twitter Email Copy Link Print
Leave a comment Leave a comment

Leave a Reply Cancel reply

Your email address will not be published. Required fields are marked *

POPULAR POSTS

Advertisement

FACT CHECK: Video showing ‘bridge collapsing in Nasarawa’ is AI-generated

A video showing a bridge collapse incident is circulating across social media platforms, especially on…

July 24, 2025

MISINFO ALERT: Viral video of ‘foreign arms dealer’ in Zamfara is from 2021, says army

The Nigerian Army says a viral video claiming the arrest of a foreign arms dealer…

July 24, 2025

Ókwú Badenoch nà ụ́mụ̀ yá ápụ̀ghị̀ ínwétá íkíké ị́bụ ńdị́ Naijiria bụ̀ àsị́

Kemi Badenoch, onye ndú òtù Conservative Party nke obodo United Kingdom, ekwuola na ọ gaghị…

July 22, 2025

Kemi Badenoch claim sey her children no fit get Nigerian citizenship but she no tok true

Kemi Badenoch, leader of di United Kingdom Conservative Party, claim sey she no fit pass…

July 22, 2025
Advertisement
Advertisement

YOU MAY ALSO LIKE

Ókwú Badenoch nà ụ́mụ̀ yá ápụ̀ghị̀ ínwétá íkíké ị́bụ ńdị́ Naijiria bụ̀ àsị́

Kemi Badenoch, onye ndú òtù Conservative Party nke obodo United Kingdom, ekwuola na ọ gaghị enyenwu ụmụ ya ikike ịbụ…

CHECK AM FOR WAZOBIA
July 22, 2025

Kemi Badenoch claim sey her children no fit get Nigerian citizenship but she no tok true

Kemi Badenoch, leader of di United Kingdom Conservative Party, claim sey she no fit pass her right of Nigerian citizenship…

CHECK AM FOR WAZOBIA
July 22, 2025

Irọ́ ni Kemi Badenoch pa pé òfin kò fààyè gba àwọn ọmọ òhun láti di ọmọ Nàìjíríà

Kemi Badenoch, arábìnrin tó jẹ́ olórí ẹgbẹ́ òsèlú alátakò tí wọ́n ń pè ní Conservative Party ní orílẹ̀ èdè United…

CHECK AM FOR WAZOBIA
July 22, 2025

Maganar Kemi Badenoch na cewa ‘ya’yanta ba za su iya samun shaidar zama dan Najeriya ba karya ne

Kemi Badenoch, shugabar jam'iyyar masu ra'ayin rikau ta Burtaniya, ta yi ikirarin cewa ba za ta iya mika hakkinta na…

CHECK AM FOR WAZOBIA
July 22, 2025

CableCheck seeks to provide reliable tools and resources for readers to tackle the menace of fake and misleading materials constantly pushed into the public space from various sources. We monitor the accuracy of claims made in traditional and social media. We also provide a tracker to hold politicians and policymakers accountable for the plans and promises they make to the public. CableCheck is a project of the Cable Newspaper Journalism Foundation (CNJF), supported by the MacArthur Foundation and implemented by TheCable newspaper.

Follow US: 

LINKS

  • Contact
  • About Us
  • Non-Partisanship Policy
  • Funding
  • Correction Policy
© Copyright TheCable. All Rights reserved.
Welcome Back!

Sign in to your account

Lost your password?