TheCable Fact Check
  • Home
  • Fact Check
  • Fake News
  • Check Am For Wazobia
Reading: Irọ ni pé ọrọ̀ ajé láti orílẹ̀ èdè mìíràn kò wọ Ìpínlẹ̀ Kaduna láti ìgbà tí El-Rufai tí kúrò nípò gómìnà
Share
Latest News
FACT CHECK: No, Emefiele didn’t return N4trn to FG
Rárá, Nàìjíríà kò fi àwọn ọmọ iṣẹ́ ológun rán sẹ sí Ísírẹ́lì láti dá rògbòdìyàn tó ń ṣẹlẹ̀ níbẹ̀ dúró
Ḿbà, Naijiria ézipụ̀ghị̀ ńdị́ ágha ńkwàdó ùdó nà òbòdò Isreal
No, Nigeria no send peace support mission go Israel
A’a, Najeriya ba ta tura tawagar taimakon zaman lafiya zuwa Isra’ila ba
Ǹjẹ́ Tinubu àti Alexander Zingman lọ sí ilé-ìwé kan náà? Èyí ni ohun tí a mọ̀
Tinubu nà Alexander Zingman ọ̀ gàrà ótù ụ́lọ̀ákwụ́kwọ́? Lèé íhé ányị́ mà
Tinubu go di same school wit Alexander Zingman? Na wetin we sabi be dis
Advertisement
Aa
TheCable Fact CheckTheCable Fact Check
Search
  • Home
  • Fact Check
  • Fake News
  • Check Am For Wazobia
Follow US

Irọ ni pé ọrọ̀ ajé láti orílẹ̀ èdè mìíràn kò wọ Ìpínlẹ̀ Kaduna láti ìgbà tí El-Rufai tí kúrò nípò gómìnà

Yemi Michael
By Yemi Michael Published March 6, 2025 4 Min Read
Share

Ẹni kan, tí wọ́n ń pè ní @xagreat, tó ń lo X, tí a mọ̀ sí Twitter tẹ́lẹ̀, ohun ìgbàlódé ibaraẹnise orí ayélujára, sọ pé ọrọ̀ ajé kankan kò wá sí Ìpínlẹ̀ Kaduna láti ìgbà tí Nasir el-Rufai, gómìnà Ìpínlẹ̀ Kaduna nígbàkanrí, ti kúrò ní ipò gómìnà.

Ẹni tó sọ̀rọ̀ yìí, sọ pé, nígbà tí eto ìdìbò 2027 bá dé, àwọn yóò fi ìbò yọ Uba Sani, gómìnà Ìpínlẹ̀ náà nísìnyìí, láti lè jẹ́ kí Ìpínlẹ̀ náà dàgbà sókè.

“Láti ìgbà tí El-Rufai tí fi ipò gómìnà sílẹ̀, ọrọ̀ ajé (Foreign Direct Investment-FDI) kankan kò wá sí Ìpínlẹ̀ Kaduna. Eléyìí ni wọ́n ń pè ní ilọsẹhin,” báyìí ni ẹni yìí se wí.

“A máa fi ẹ̀yìn Uba Sani tì ní ọdún 2027, láti lè gba Kaduna sílẹ̀ lọ́wọ́ ilọsẹhin.”

Àwọn ènìyàn ẹgbẹ̀rún mẹ́rìnlá ló ti rí/wo ọ̀rọ̀ yìí, àwọn ènìyàn òjìlénígba ó dín mẹ́jọ ló fẹ́ràn ọ̀rọ̀ yìí, àwọn ènìyàn mejidinlọgọrin ló pin in nígbà tí a wòó ní ọjọ́ kẹrin, oṣù kẹta, ọdún 2025.

KÍ NI ÌDÍ TÍ ỌRỌ̀ AJÉ LÁTI ORÍLẸ̀ ÈDÈ MÍRÀN (FDI) SE SE KÓKÓ?

FDI jẹ́ ọrọ̀ ajé láti orílẹ̀ èdè kan tí ó ń wọ/wá sí orílẹ̀ èdè mìíràn tí ó máa wà níbẹ̀ fún ìgbà pipẹ. 

Ó jẹ́ ohun tí ó máa ń jẹ́ kí ìdàgbàsókè wà níbi tí ó bá wà. Àwọn ohun tí a lè pè ní ìdàgbàsókè lè jẹ́ isẹ pípèsè fún àwọn ènìyàn, owó tí ìjọba máa rí ní owó orí, àwọn owó mìíràn tí wọ́n máa rí, ó sì tún máa ń jẹ́ kí ìjọba rí owó fi pamọ sí orílẹ̀ èdè mìíràn.

FDI tún máa ń jẹ́ kí a mọ bí ibì kan se n dàgbà sókè tàbí ní ìlọsíwájú si, èyí tí ó túmọ̀ sí pé ibi tí kò bá ní irú ọrọ̀ ajé yìí kò lọ síwájú.

AYẸWO Ọ̀RỌ̀ YÌÍ TÍ THECABLE NEWSPAPER SE RÈÉ 

Wọ́n búra fún Sani gẹ́gẹ́bí gómìnà ní ọjọ́ kọkàndínlógún, oṣù karùn-ún, ọdún 2023.

CableCheck se àyẹ̀wò àwọn ọrọ̀ ajé láti àwọn orílẹ̀ èdè mìíràn tí National Bureau of Statistics (NBS), àjọ tó ń ṣètò kíka nǹkan, fi síta fún oṣù keje sí oṣù kẹsàn-án (third quarter-Q3), ọdún 2023 sí oṣù keje sí oṣù kẹsàn-án, ọdún 2024 (third quarter-Q3, 2024.

Atẹsita NBS fi hàn pé Kaduna kò ní FDI láti oṣù keje sí oṣù kẹsàn-án, ọdún 2023 sí oṣù kẹrin sí oṣù kẹfà (second quarter-Q2), ọdún 2024.

Ninu atẹsita fún FDI fún ọdún 2024, NBS sọ pé FDI tí owó ẹ̀ tó biliọnu méjì dín ní aadọta mílíọ̀nù dọ́là ní o wọlé sí Ìpínlẹ̀ Kaduna ní oṣù keje sí oṣù kẹsàn-án, ọdún 2024.

NBS sọ pé Kaduna wà lára àwọn Ìpínlẹ̀ márùn-ún tí ó ní FDI, ní oṣù keje sí oṣù kẹsàn-án, ọdún 2024, èyí tí owó ẹ̀ tó biliọnu kan àti mílíọ̀nù marundinlọgọrun dọ́là, eléyìí tí ó jẹ́ bí ìdá kan lára gbogbo FDI, tí owó ẹ̀ jẹ́ biliọnu kan àti mílíọ̀nù igba àti àádọ́ta, tó wọlé sí Nàìjíríà láàárín oṣù keje sí oṣù kẹsàn-án, ọdún 2024.

BÍ A SE RÍ Ọ̀RỌ̀ YÌÍ ṢÍ 

Ọ̀rọ̀ tí @xagreat sọ yìí kìí se òótọ́.

TAGGED: Fact Check, Fact check in Yoruba, FDI, kaduna state, Nasir el-Rufai, News in Yorùbá, Uba Sani

Please send your feedback, claims to fact check and corrections requests to [email protected]

Yemi Michael March 6, 2025 March 6, 2025
Share this Article
Facebook Twitter Email Copy Link Print
Leave a comment Leave a comment

Leave a Reply Cancel reply

Your email address will not be published. Required fields are marked *

POPULAR POSTS

Advertisement

FACT CHECK: No, Emefiele didn’t return N4trn to FG

A video circulating on social media shows a Facebook user claiming Godwin Emefiele, the former…

July 2, 2025

Rárá, Nàìjíríà kò fi àwọn ọmọ iṣẹ́ ológun rán sẹ sí Ísírẹ́lì láti dá rògbòdìyàn tó ń ṣẹlẹ̀ níbẹ̀ dúró

Ìròyìn lati inú fídíò Facebook kan sọ pé Nàìjíríà fi àwọn ọmọ ogun ránṣẹ́ sí…

June 28, 2025

Ḿbà, Naijiria ézipụ̀ghị̀ ńdị́ ágha ńkwàdó ùdó nà òbòdò Isreal

Ótù ihe ngosị si na Facebook kwuru na Naijiria zipụrụ ndị agha ka ha gaa…

June 28, 2025

No, Nigeria no send peace support mission go Israel

One Facebook video claim sey Nigeria send soldiers go Israel for joint peace support mission.…

June 28, 2025
Advertisement
Advertisement

YOU MAY ALSO LIKE

Rárá, Nàìjíríà kò fi àwọn ọmọ iṣẹ́ ológun rán sẹ sí Ísírẹ́lì láti dá rògbòdìyàn tó ń ṣẹlẹ̀ níbẹ̀ dúró

Ìròyìn lati inú fídíò Facebook kan sọ pé Nàìjíríà fi àwọn ọmọ ogun ránṣẹ́ sí orílẹ̀ èdè Ísírẹ́lì kí rògbòdìyàn…

CHECK AM FOR WAZOBIA
June 28, 2025

Ḿbà, Naijiria ézipụ̀ghị̀ ńdị́ ágha ńkwàdó ùdó nà òbòdò Isreal

Ótù ihe ngosị si na Facebook kwuru na Naijiria zipụrụ ndị agha ka ha gaa kwàdó udo na mba Isreal.…

CHECK AM FOR WAZOBIA
June 28, 2025

No, Nigeria no send peace support mission go Israel

One Facebook video claim sey Nigeria send soldiers go Israel for joint peace support mission. One male broadcaster wey dey…

CHECK AM FOR WAZOBIA
June 28, 2025

A’a, Najeriya ba ta tura tawagar taimakon zaman lafiya zuwa Isra’ila ba

Wani faifan bidiyo na Facebook ya nuna cewa Najeriya ta tura dakaru domin aikin hadin gwiwa na tallafawa zaman lafiya…

CHECK AM FOR WAZOBIA
June 28, 2025

CableCheck seeks to provide reliable tools and resources for readers to tackle the menace of fake and misleading materials constantly pushed into the public space from various sources. We monitor the accuracy of claims made in traditional and social media. We also provide a tracker to hold politicians and policymakers accountable for the plans and promises they make to the public. CableCheck is a project of the Cable Newspaper Journalism Foundation (CNJF), supported by the MacArthur Foundation and implemented by TheCable newspaper.

Follow US: 

LINKS

  • Contact
  • About Us
  • Non-Partisanship Policy
  • Funding
  • Correction Policy
© Copyright TheCable. All Rights reserved.
Welcome Back!

Sign in to your account

Lost your password?