TheCable Fact Check
  • Home
  • Fact Check
  • Fake News
  • Check Am For Wazobia
Reading: Irọ ni pé ọrọ̀ ajé láti orílẹ̀ èdè mìíràn kò wọ Ìpínlẹ̀ Kaduna láti ìgbà tí El-Rufai tí kúrò nípò gómìnà
Share
Latest News
Ị́hé ńgósị́ ébé ńdị́ ụ́ká Naijiria jị́ égbè n’ụ́lọ́ ụ́ká ézị́ghị́ézị́
Hotunan da ke yawo na kiristocin Najeriya rike da makamai a coci suna yaudarar
Àwọn fọ́tò tó sàfihàn àwọn ọmọ Nàìjíríà ẹlẹ́sìn Kristẹni tí wọ́n di nnkan ìjà mọ́ra kò seé gbàgbọ́
Viral foto wey show as Nigerian Christians dey cari gun for church dey mislead pipu
FACT CHECK: Viral photos of Nigerian Christians bearing arms in churches are misleading
Da’awar cewa Davido da Chioma suna tsammanin ɗansu na uku karya ne
Òótọ́ kọ́ ni ọ̀rọ̀ tó sọ pé Davido àti Chioma ń gbaradì fún ọmọ wọn kẹta
Evidence no dey sey Davido and Chioma dey expect dia third pikin
Advertisement
Aa
TheCable Fact CheckTheCable Fact Check
Search
  • Home
  • Fact Check
  • Fake News
  • Check Am For Wazobia
Follow US

Irọ ni pé ọrọ̀ ajé láti orílẹ̀ èdè mìíràn kò wọ Ìpínlẹ̀ Kaduna láti ìgbà tí El-Rufai tí kúrò nípò gómìnà

Yemi Michael
By Yemi Michael Published March 6, 2025 4 Min Read
Share

Ẹni kan, tí wọ́n ń pè ní @xagreat, tó ń lo X, tí a mọ̀ sí Twitter tẹ́lẹ̀, ohun ìgbàlódé ibaraẹnise orí ayélujára, sọ pé ọrọ̀ ajé kankan kò wá sí Ìpínlẹ̀ Kaduna láti ìgbà tí Nasir el-Rufai, gómìnà Ìpínlẹ̀ Kaduna nígbàkanrí, ti kúrò ní ipò gómìnà.

Ẹni tó sọ̀rọ̀ yìí, sọ pé, nígbà tí eto ìdìbò 2027 bá dé, àwọn yóò fi ìbò yọ Uba Sani, gómìnà Ìpínlẹ̀ náà nísìnyìí, láti lè jẹ́ kí Ìpínlẹ̀ náà dàgbà sókè.

“Láti ìgbà tí El-Rufai tí fi ipò gómìnà sílẹ̀, ọrọ̀ ajé (Foreign Direct Investment-FDI) kankan kò wá sí Ìpínlẹ̀ Kaduna. Eléyìí ni wọ́n ń pè ní ilọsẹhin,” báyìí ni ẹni yìí se wí.

“A máa fi ẹ̀yìn Uba Sani tì ní ọdún 2027, láti lè gba Kaduna sílẹ̀ lọ́wọ́ ilọsẹhin.”

Àwọn ènìyàn ẹgbẹ̀rún mẹ́rìnlá ló ti rí/wo ọ̀rọ̀ yìí, àwọn ènìyàn òjìlénígba ó dín mẹ́jọ ló fẹ́ràn ọ̀rọ̀ yìí, àwọn ènìyàn mejidinlọgọrin ló pin in nígbà tí a wòó ní ọjọ́ kẹrin, oṣù kẹta, ọdún 2025.

KÍ NI ÌDÍ TÍ ỌRỌ̀ AJÉ LÁTI ORÍLẸ̀ ÈDÈ MÍRÀN (FDI) SE SE KÓKÓ?

FDI jẹ́ ọrọ̀ ajé láti orílẹ̀ èdè kan tí ó ń wọ/wá sí orílẹ̀ èdè mìíràn tí ó máa wà níbẹ̀ fún ìgbà pipẹ. 

Ó jẹ́ ohun tí ó máa ń jẹ́ kí ìdàgbàsókè wà níbi tí ó bá wà. Àwọn ohun tí a lè pè ní ìdàgbàsókè lè jẹ́ isẹ pípèsè fún àwọn ènìyàn, owó tí ìjọba máa rí ní owó orí, àwọn owó mìíràn tí wọ́n máa rí, ó sì tún máa ń jẹ́ kí ìjọba rí owó fi pamọ sí orílẹ̀ èdè mìíràn.

FDI tún máa ń jẹ́ kí a mọ bí ibì kan se n dàgbà sókè tàbí ní ìlọsíwájú si, èyí tí ó túmọ̀ sí pé ibi tí kò bá ní irú ọrọ̀ ajé yìí kò lọ síwájú.

AYẸWO Ọ̀RỌ̀ YÌÍ TÍ THECABLE NEWSPAPER SE RÈÉ 

Wọ́n búra fún Sani gẹ́gẹ́bí gómìnà ní ọjọ́ kọkàndínlógún, oṣù karùn-ún, ọdún 2023.

CableCheck se àyẹ̀wò àwọn ọrọ̀ ajé láti àwọn orílẹ̀ èdè mìíràn tí National Bureau of Statistics (NBS), àjọ tó ń ṣètò kíka nǹkan, fi síta fún oṣù keje sí oṣù kẹsàn-án (third quarter-Q3), ọdún 2023 sí oṣù keje sí oṣù kẹsàn-án, ọdún 2024 (third quarter-Q3, 2024.

Atẹsita NBS fi hàn pé Kaduna kò ní FDI láti oṣù keje sí oṣù kẹsàn-án, ọdún 2023 sí oṣù kẹrin sí oṣù kẹfà (second quarter-Q2), ọdún 2024.

Ninu atẹsita fún FDI fún ọdún 2024, NBS sọ pé FDI tí owó ẹ̀ tó biliọnu méjì dín ní aadọta mílíọ̀nù dọ́là ní o wọlé sí Ìpínlẹ̀ Kaduna ní oṣù keje sí oṣù kẹsàn-án, ọdún 2024.

NBS sọ pé Kaduna wà lára àwọn Ìpínlẹ̀ márùn-ún tí ó ní FDI, ní oṣù keje sí oṣù kẹsàn-án, ọdún 2024, èyí tí owó ẹ̀ tó biliọnu kan àti mílíọ̀nù marundinlọgọrun dọ́là, eléyìí tí ó jẹ́ bí ìdá kan lára gbogbo FDI, tí owó ẹ̀ jẹ́ biliọnu kan àti mílíọ̀nù igba àti àádọ́ta, tó wọlé sí Nàìjíríà láàárín oṣù keje sí oṣù kẹsàn-án, ọdún 2024.

BÍ A SE RÍ Ọ̀RỌ̀ YÌÍ ṢÍ 

Ọ̀rọ̀ tí @xagreat sọ yìí kìí se òótọ́.

TAGGED: Fact Check, Fact check in Yoruba, FDI, kaduna state, Nasir el-Rufai, News in Yorùbá, Uba Sani

Please send your feedback, claims to fact check and corrections requests to [email protected]

Yemi Michael March 6, 2025 March 6, 2025
Share this Article
Facebook Twitter Email Copy Link Print
Leave a comment Leave a comment

Leave a Reply Cancel reply

Your email address will not be published. Required fields are marked *

POPULAR POSTS

Advertisement

Ị́hé ńgósị́ ébé ńdị́ ụ́ká Naijiria jị́ égbè n’ụ́lọ́ ụ́ká ézị́ghị́ézị́

Ka ndị omekome wakpochara ndị gara ụka na Christ Apostolic Church (CAC) dị na Oke…

December 4, 2025

Hotunan da ke yawo na kiristocin Najeriya rike da makamai a coci suna yaudarar

Biyo bayan harin da wasu ‘yan bindiga suka kai kan mabiya cocin Christ Apostolic Church…

December 4, 2025

Àwọn fọ́tò tó sàfihàn àwọn ọmọ Nàìjíríà ẹlẹ́sìn Kristẹni tí wọ́n di nnkan ìjà mọ́ra kò seé gbàgbọ́

Lẹ́hìn ìgbà tí àwọn oníwà jàgídíjàgan kan kọlu àwọn ènìyàn tí wọ́n ń jọ́sìn ní…

December 4, 2025

Viral foto wey show as Nigerian Christians dey cari gun for church dey mislead pipu

Afta bandits attack worshippers Christ Apostolic Church (CAC) branch for Oke Isegun inside di Eruku…

December 4, 2025
Advertisement
Advertisement

YOU MAY ALSO LIKE

Ị́hé ńgósị́ ébé ńdị́ ụ́ká Naijiria jị́ égbè n’ụ́lọ́ ụ́ká ézị́ghị́ézị́

Ka ndị omekome wakpochara ndị gara ụka na Christ Apostolic Church (CAC) dị na Oke Isegun n'obodo Eruku nke Kwara…

CHECK AM FOR WAZOBIA
December 4, 2025

Hotunan da ke yawo na kiristocin Najeriya rike da makamai a coci suna yaudarar

Biyo bayan harin da wasu ‘yan bindiga suka kai kan mabiya cocin Christ Apostolic Church (CAC) a reshen cocin Christ…

CHECK AM FOR WAZOBIA
December 4, 2025

Àwọn fọ́tò tó sàfihàn àwọn ọmọ Nàìjíríà ẹlẹ́sìn Kristẹni tí wọ́n di nnkan ìjà mọ́ra kò seé gbàgbọ́

Lẹ́hìn ìgbà tí àwọn oníwà jàgídíjàgan kan kọlu àwọn ènìyàn tí wọ́n ń jọ́sìn ní ẹ̀ka Christ Apostolic Church (CAC)…

CHECK AM FOR WAZOBIA
December 4, 2025

Viral foto wey show as Nigerian Christians dey cari gun for church dey mislead pipu

Afta bandits attack worshippers Christ Apostolic Church (CAC) branch for Oke Isegun inside di Eruku community for Kwara state on…

CHECK AM FOR WAZOBIA
December 4, 2025

CableCheck seeks to provide reliable tools and resources for readers to tackle the menace of fake and misleading materials constantly pushed into the public space from various sources. We monitor the accuracy of claims made in traditional and social media. We also provide a tracker to hold politicians and policymakers accountable for the plans and promises they make to the public. CableCheck is a project of the Cable Newspaper Journalism Foundation (CNJF), supported by the MacArthur Foundation and implemented by TheCable newspaper.

Follow US: 

LINKS

  • Contact
  • About Us
  • Non-Partisanship Policy
  • Funding
  • Correction Policy
© Copyright TheCable. All Rights reserved.
Welcome Back!

Sign in to your account

Lost your password?