TheCable Fact Check
  • Home
  • Fact Check
  • Fake News
  • Check Am For Wazobia
Reading: Wọn kò yin ìbọn pá ọmọkùnrin kan soso tí Wike bí ní orílẹ̀-èdè Amẹ́ríkà
Share
Latest News
FACT CHECK: Is Nigeria 4th fastest-growing economy in the world in 2025?
FACT CHECK: How true are Obi’s claims about poverty rate in Nigeria, China and Indonesia?
FACT CHECK: No, Finnish court didn’t approve Simon Ekpa’s extradition to Nigeria
FACT CHECK: Is Cardinal Arinze eligible to be elected as the next Pope?
Rárá, Jonathan kò sọ pé Tinubu yóò se àṣeyọrí nínú ètò ìdìbò fún Ipò Ààrẹ ní ọdún 2027
A’a, Jonathan bai yi hasashen nasarar Tinubu a zaben shugaban kasa na 2027 ba
No, Jonathan no predict Tinubu victory for 2027 presidential election
Ḿbà, Jonathan ágbaghị àmà na Tinubu gà-èmérí ńtùlíáka ónyé ísíàlà ǹkè áfọ̀ 2027
Advertisement
Aa
TheCable Fact CheckTheCable Fact Check
Search
  • Home
  • Fact Check
  • Fake News
  • Check Am For Wazobia
Follow US

Wọn kò yin ìbọn pá ọmọkùnrin kan soso tí Wike bí ní orílẹ̀-èdè Amẹ́ríkà

Yemi Michael
By Yemi Michael Published March 9, 2023 2 Min Read
Share

Atẹjade/ìròyìn kan lórí ayélujára tí sọ wí pé wọn yin ìbọn pá ọmokùnrin kan soso tí Nyesom Wike, Gómìnà Ìpínlẹ̀ Rivers bí ní ìlú California, ní orílẹ̀-èdè Amẹ́ríkà. 

Atẹjade tí àwọn ènìyàn ń pín kiri náà sọ wí pé wọn pa ọmọ náà nítorí ipa tí bàbá rẹ̀ kó nínú ìbò Ààrẹ tí a se kọjá ní ọjọ́ Àbámẹ́ta (Satide) ni Nàìjíríà.

“ìfitónilétí ìròyìn tí ó sẹsẹ ṣẹlẹ̀: wọn yínbọn pa ọmọkùnrin kan soso tí Wike bí ní California, orílẹ̀-èdè Amẹ́ríkà nítorí ipa tí bàbá rẹ̀ kó nínú ìdìbò Ìpínlẹ̀ Rivers,” báyìí ni àkòrí ìkan nínú àwọn atẹjade náà wí.

“A fi yé wa pé ọmọkùnrin kan tí a kò dámọ̀ tí ó jẹ́ ọmọ ọdún méjìdínlógún ni ó yínbọn paá nítorí ipa tí bàbá rẹ̀ kó nínú ìdìbò Ìpínlẹ̀ Rivers.

Èsì ìwádìí tí a se kò ṣeé gbára lé. Èyí túmọ̀ sí pé ọ̀rọ̀ náà kìí se òótọ́/òtítọ́.

Ayẹwo tí ìwé ìròyìn TheCable se fi yé wa pé kò sí ìwé ìròyìn tí isẹ́ wọn dangajiya/tí ó ṣeé gbé ara lé tí ó sọ ọ̀rọ̀ tí ó ṣeé dimu nípa ọ̀rọ̀ yìí. Irọ́/ahesọ lásán-làsàn ni ọ̀rọ̀ yìí.

Àwọn tí ó gbé ìròyìn náà jáde lo àwòrán Wike pẹ̀lú ọmọkùnrin kan tí ó wọ aṣọ asekagba/ìparí ẹ̀kọ́ tí àwọn akẹ́kọ̀ọ́ máa ń wọ (gaun giraduesọn).

Ayẹwo àwòrán náà tí a se ní orí ayélujára fi yé wa pé àwòrán náà kọ́kọ́ jáde ní orí ayélujára nínú osù keje, ọdún 2022.

Jordan Nyesom-Wike, son of the Rivers State Governor, Nyesom Wike has graduated from the University of Exeter, in the United Kingdom… pls can u see why they are not talking about ASUU strike. Well Congratulations pic.twitter.com/tFvFnmmKpQ

— Odinala Ndi IGBO (@enyinnayaibeka) July 11, 2022

Gẹ́gẹ́bí àkòrí àwòrán náà tí ìwé ìròyìn The Nation gbé jáde, wọ́n ya àwòrán náà nígbà tí Gómìnà náà àti àwọn ẹbí rẹ̀ lọ sí ibi ajọyọ ìparí ẹ̀kọ́ ọmọ rẹ̀ ọkùnrin, ẹni tí àwọn oniroyin ofege/irọ́ ní orí ayélujára sọ wí pé wọn yinbọn pa ní orílẹ̀-èdè Amẹ́ríkà.

Nígbà tí o sọ ọ̀rọ̀ nípa atẹjade yìí, Kelvin Ebiri, ẹni tí ó jẹ́ oluranlọwọ fún àwọn ọ̀rọ̀ orí ayélujára fún Gómìnà Wike sọ wí pé ọ̀rọ̀ yìí kìí se òtítọ́. Irọ́ ńlá gbáà ni.

Please send your feedback, claims to fact check and corrections requests to [email protected]

Yemi Michael March 9, 2023 March 9, 2023
Share this Article
Facebook Twitter Email Copy Link Print
Leave a comment Leave a comment

Leave a Reply Cancel reply

Your email address will not be published. Required fields are marked *

POPULAR POSTS

Advertisement

FACT CHECK: Is Nigeria 4th fastest-growing economy in the world in 2025?

A viral post claims, based on International Monetary Fund (IMF) projections, that Nigeria ranks fourth…

May 9, 2025

FACT CHECK: How true are Obi’s claims about poverty rate in Nigeria, China and Indonesia?

Peter Obi, Labour Party (LP) presidential candidate in the 2023 elections, sparked a debate with…

May 5, 2025

FACT CHECK: No, Finnish court didn’t approve Simon Ekpa’s extradition to Nigeria

On Tuesday, some social media users and blog sites made a post claiming that a…

April 24, 2025

FACT CHECK: Is Cardinal Arinze eligible to be elected as the next Pope?

A social media user has claimed that Francis Arinze, a Roman Catholic cardinal, is the…

April 21, 2025
Advertisement
Advertisement

YOU MAY ALSO LIKE

Rárá, Jonathan kò sọ pé Tinubu yóò se àṣeyọrí nínú ètò ìdìbò fún Ipò Ààrẹ ní ọdún 2027

Ní ọjọ́ ajé, ọ̀rọ̀ kan to sọ pé Goodluck Jonathan, Ààrẹ orílẹ̀ èdè Nàìjíríà tẹ́lẹ̀ sọ pé Ààrẹ Bọla Tinubu…

CHECK AM FOR WAZOBIA
April 20, 2025

A’a, Jonathan bai yi hasashen nasarar Tinubu a zaben shugaban kasa na 2027 ba

A ranar Talata ne wani rahoto da ke ikirarin cewa tsohon shugaban kasa Goodluck Jonathan ya yi hasashen nasarar Shugaba…

CHECK AM FOR WAZOBIA
April 20, 2025

No, Jonathan no predict Tinubu victory for 2027 presidential election

On Tuesday, one report wey claim sey former President Goodluck Jonathan predict President Bola Tinubu victory for di 2027 presidential…

CHECK AM FOR WAZOBIA
April 20, 2025

Ḿbà, Jonathan ágbaghị àmà na Tinubu gà-èmérí ńtùlíáka ónyé ísíàlà ǹkè áfọ̀ 2027

N’ubọchị Tuesde, ozi na-ekwu na onye bụburu onye isiala Naijiria, bụ Goodluck Jonathan, gbara àmà na onyeisiala Bola Tinubu ga-emeri…

CHECK AM FOR WAZOBIA
April 19, 2025

CableCheck seeks to provide reliable tools and resources for readers to tackle the menace of fake and misleading materials constantly pushed into the public space from various sources. We monitor the accuracy of claims made in traditional and social media. We also provide a tracker to hold politicians and policymakers accountable for the plans and promises they make to the public. CableCheck is a project of the Cable Newspaper Journalism Foundation (CNJF), supported by the MacArthur Foundation and implemented by TheCable newspaper.

Follow US: 

LINKS

  • Contact
  • About Us
  • Non-Partisanship Policy
  • Funding
  • Correction Policy
© Copyright TheCable. All Rights reserved.
Welcome Back!

Sign in to your account

Lost your password?