TheCable Fact Check
  • Home
  • Fact Check
  • Fake News
  • Check Am For Wazobia
Reading: Wọn kò yin ìbọn pá ọmọkùnrin kan soso tí Wike bí ní orílẹ̀-èdè Amẹ́ríkà
Share
Latest News
Rárá, Nàìjíríà kò fi àwọn ọmọ iṣẹ́ ológun rán sẹ sí Ísírẹ́lì láti dá rògbòdìyàn tó ń ṣẹlẹ̀ níbẹ̀ dúró
Ḿbà, Naijiria ézipụ̀ghị̀ ńdị́ ágha ńkwàdó ùdó nà òbòdò Isreal
No, Nigeria no send peace support mission go Israel
A’a, Najeriya ba ta tura tawagar taimakon zaman lafiya zuwa Isra’ila ba
Ǹjẹ́ Tinubu àti Alexander Zingman lọ sí ilé-ìwé kan náà? Èyí ni ohun tí a mọ̀
Tinubu nà Alexander Zingman ọ̀ gàrà ótù ụ́lọ̀ákwụ́kwọ́? Lèé íhé ányị́ mà
Tinubu go di same school wit Alexander Zingman? Na wetin we sabi be dis
Shin Tinubu ya halarci makaranta daya da Alexander Zingman? Ga abin da muka sani
Advertisement
Aa
TheCable Fact CheckTheCable Fact Check
Search
  • Home
  • Fact Check
  • Fake News
  • Check Am For Wazobia
Follow US

Wọn kò yin ìbọn pá ọmọkùnrin kan soso tí Wike bí ní orílẹ̀-èdè Amẹ́ríkà

Yemi Michael
By Yemi Michael Published March 9, 2023 2 Min Read
Share

Atẹjade/ìròyìn kan lórí ayélujára tí sọ wí pé wọn yin ìbọn pá ọmokùnrin kan soso tí Nyesom Wike, Gómìnà Ìpínlẹ̀ Rivers bí ní ìlú California, ní orílẹ̀-èdè Amẹ́ríkà. 

Atẹjade tí àwọn ènìyàn ń pín kiri náà sọ wí pé wọn pa ọmọ náà nítorí ipa tí bàbá rẹ̀ kó nínú ìbò Ààrẹ tí a se kọjá ní ọjọ́ Àbámẹ́ta (Satide) ni Nàìjíríà.

“ìfitónilétí ìròyìn tí ó sẹsẹ ṣẹlẹ̀: wọn yínbọn pa ọmọkùnrin kan soso tí Wike bí ní California, orílẹ̀-èdè Amẹ́ríkà nítorí ipa tí bàbá rẹ̀ kó nínú ìdìbò Ìpínlẹ̀ Rivers,” báyìí ni àkòrí ìkan nínú àwọn atẹjade náà wí.

“A fi yé wa pé ọmọkùnrin kan tí a kò dámọ̀ tí ó jẹ́ ọmọ ọdún méjìdínlógún ni ó yínbọn paá nítorí ipa tí bàbá rẹ̀ kó nínú ìdìbò Ìpínlẹ̀ Rivers.

Èsì ìwádìí tí a se kò ṣeé gbára lé. Èyí túmọ̀ sí pé ọ̀rọ̀ náà kìí se òótọ́/òtítọ́.

Ayẹwo tí ìwé ìròyìn TheCable se fi yé wa pé kò sí ìwé ìròyìn tí isẹ́ wọn dangajiya/tí ó ṣeé gbé ara lé tí ó sọ ọ̀rọ̀ tí ó ṣeé dimu nípa ọ̀rọ̀ yìí. Irọ́/ahesọ lásán-làsàn ni ọ̀rọ̀ yìí.

Àwọn tí ó gbé ìròyìn náà jáde lo àwòrán Wike pẹ̀lú ọmọkùnrin kan tí ó wọ aṣọ asekagba/ìparí ẹ̀kọ́ tí àwọn akẹ́kọ̀ọ́ máa ń wọ (gaun giraduesọn).

Ayẹwo àwòrán náà tí a se ní orí ayélujára fi yé wa pé àwòrán náà kọ́kọ́ jáde ní orí ayélujára nínú osù keje, ọdún 2022.

Jordan Nyesom-Wike, son of the Rivers State Governor, Nyesom Wike has graduated from the University of Exeter, in the United Kingdom… pls can u see why they are not talking about ASUU strike. Well Congratulations pic.twitter.com/tFvFnmmKpQ

— Odinala Ndi IGBO (@enyinnayaibeka) July 11, 2022

Gẹ́gẹ́bí àkòrí àwòrán náà tí ìwé ìròyìn The Nation gbé jáde, wọ́n ya àwòrán náà nígbà tí Gómìnà náà àti àwọn ẹbí rẹ̀ lọ sí ibi ajọyọ ìparí ẹ̀kọ́ ọmọ rẹ̀ ọkùnrin, ẹni tí àwọn oniroyin ofege/irọ́ ní orí ayélujára sọ wí pé wọn yinbọn pa ní orílẹ̀-èdè Amẹ́ríkà.

Nígbà tí o sọ ọ̀rọ̀ nípa atẹjade yìí, Kelvin Ebiri, ẹni tí ó jẹ́ oluranlọwọ fún àwọn ọ̀rọ̀ orí ayélujára fún Gómìnà Wike sọ wí pé ọ̀rọ̀ yìí kìí se òtítọ́. Irọ́ ńlá gbáà ni.

Please send your feedback, claims to fact check and corrections requests to [email protected]

Yemi Michael March 9, 2023 March 9, 2023
Share this Article
Facebook Twitter Email Copy Link Print
Leave a comment Leave a comment

Leave a Reply Cancel reply

Your email address will not be published. Required fields are marked *

POPULAR POSTS

Advertisement

Rárá, Nàìjíríà kò fi àwọn ọmọ iṣẹ́ ológun rán sẹ sí Ísírẹ́lì láti dá rògbòdìyàn tó ń ṣẹlẹ̀ níbẹ̀ dúró

Ìròyìn lati inú fídíò Facebook kan sọ pé Nàìjíríà fi àwọn ọmọ ogun ránṣẹ́ sí…

June 28, 2025

Ḿbà, Naijiria ézipụ̀ghị̀ ńdị́ ágha ńkwàdó ùdó nà òbòdò Isreal

Ótù ihe ngosị si na Facebook kwuru na Naijiria zipụrụ ndị agha ka ha gaa…

June 28, 2025

No, Nigeria no send peace support mission go Israel

One Facebook video claim sey Nigeria send soldiers go Israel for joint peace support mission.…

June 28, 2025

A’a, Najeriya ba ta tura tawagar taimakon zaman lafiya zuwa Isra’ila ba

Wani faifan bidiyo na Facebook ya nuna cewa Najeriya ta tura dakaru domin aikin hadin…

June 28, 2025
Advertisement
Advertisement

YOU MAY ALSO LIKE

Rárá, Nàìjíríà kò fi àwọn ọmọ iṣẹ́ ológun rán sẹ sí Ísírẹ́lì láti dá rògbòdìyàn tó ń ṣẹlẹ̀ níbẹ̀ dúró

Ìròyìn lati inú fídíò Facebook kan sọ pé Nàìjíríà fi àwọn ọmọ ogun ránṣẹ́ sí orílẹ̀ èdè Ísírẹ́lì kí rògbòdìyàn…

CHECK AM FOR WAZOBIA
June 28, 2025

Ḿbà, Naijiria ézipụ̀ghị̀ ńdị́ ágha ńkwàdó ùdó nà òbòdò Isreal

Ótù ihe ngosị si na Facebook kwuru na Naijiria zipụrụ ndị agha ka ha gaa kwàdó udo na mba Isreal.…

CHECK AM FOR WAZOBIA
June 28, 2025

No, Nigeria no send peace support mission go Israel

One Facebook video claim sey Nigeria send soldiers go Israel for joint peace support mission. One male broadcaster wey dey…

CHECK AM FOR WAZOBIA
June 28, 2025

A’a, Najeriya ba ta tura tawagar taimakon zaman lafiya zuwa Isra’ila ba

Wani faifan bidiyo na Facebook ya nuna cewa Najeriya ta tura dakaru domin aikin hadin gwiwa na tallafawa zaman lafiya…

CHECK AM FOR WAZOBIA
June 28, 2025

CableCheck seeks to provide reliable tools and resources for readers to tackle the menace of fake and misleading materials constantly pushed into the public space from various sources. We monitor the accuracy of claims made in traditional and social media. We also provide a tracker to hold politicians and policymakers accountable for the plans and promises they make to the public. CableCheck is a project of the Cable Newspaper Journalism Foundation (CNJF), supported by the MacArthur Foundation and implemented by TheCable newspaper.

Follow US: 

LINKS

  • Contact
  • About Us
  • Non-Partisanship Policy
  • Funding
  • Correction Policy
© Copyright TheCable. All Rights reserved.
Welcome Back!

Sign in to your account

Lost your password?