TheCable Fact Check
  • Home
  • Fact Check
  • Fake News
  • Check Am For Wazobia
Reading: Wọn kò yin ìbọn pá ọmọkùnrin kan soso tí Wike bí ní orílẹ̀-èdè Amẹ́ríkà
Share
Latest News
FACT CHECK: Video showing ‘bridge collapsing in Nasarawa’ is AI-generated
MISINFO ALERT: Viral video of ‘foreign arms dealer’ in Zamfara is from 2021, says army
Ókwú Badenoch nà ụ́mụ̀ yá ápụ̀ghị̀ ínwétá íkíké ị́bụ ńdị́ Naijiria bụ̀ àsị́
Kemi Badenoch claim sey her children no fit get Nigerian citizenship but she no tok true
Irọ́ ni Kemi Badenoch pa pé òfin kò fààyè gba àwọn ọmọ òhun láti di ọmọ Nàìjíríà
Maganar Kemi Badenoch na cewa ‘ya’yanta ba za su iya samun shaidar zama dan Najeriya ba karya ne
FACT CHECK: Kemi Badenoch’s claim that her children can’t get Nigerian citizenship is false
Naijiria ọ̀ kàgbùrù ńkwékọ́rị́tá àzụ́máhị́á àkụ̀ ọ̀nàtàràchí yá nà US nwèrè n’íhì ḿmáchí visa?
Advertisement
Aa
TheCable Fact CheckTheCable Fact Check
Search
  • Home
  • Fact Check
  • Fake News
  • Check Am For Wazobia
Follow US

Wọn kò yin ìbọn pá ọmọkùnrin kan soso tí Wike bí ní orílẹ̀-èdè Amẹ́ríkà

Yemi Michael
By Yemi Michael Published March 9, 2023 2 Min Read
Share

Atẹjade/ìròyìn kan lórí ayélujára tí sọ wí pé wọn yin ìbọn pá ọmokùnrin kan soso tí Nyesom Wike, Gómìnà Ìpínlẹ̀ Rivers bí ní ìlú California, ní orílẹ̀-èdè Amẹ́ríkà. 

Atẹjade tí àwọn ènìyàn ń pín kiri náà sọ wí pé wọn pa ọmọ náà nítorí ipa tí bàbá rẹ̀ kó nínú ìbò Ààrẹ tí a se kọjá ní ọjọ́ Àbámẹ́ta (Satide) ni Nàìjíríà.

“ìfitónilétí ìròyìn tí ó sẹsẹ ṣẹlẹ̀: wọn yínbọn pa ọmọkùnrin kan soso tí Wike bí ní California, orílẹ̀-èdè Amẹ́ríkà nítorí ipa tí bàbá rẹ̀ kó nínú ìdìbò Ìpínlẹ̀ Rivers,” báyìí ni àkòrí ìkan nínú àwọn atẹjade náà wí.

“A fi yé wa pé ọmọkùnrin kan tí a kò dámọ̀ tí ó jẹ́ ọmọ ọdún méjìdínlógún ni ó yínbọn paá nítorí ipa tí bàbá rẹ̀ kó nínú ìdìbò Ìpínlẹ̀ Rivers.

Èsì ìwádìí tí a se kò ṣeé gbára lé. Èyí túmọ̀ sí pé ọ̀rọ̀ náà kìí se òótọ́/òtítọ́.

Ayẹwo tí ìwé ìròyìn TheCable se fi yé wa pé kò sí ìwé ìròyìn tí isẹ́ wọn dangajiya/tí ó ṣeé gbé ara lé tí ó sọ ọ̀rọ̀ tí ó ṣeé dimu nípa ọ̀rọ̀ yìí. Irọ́/ahesọ lásán-làsàn ni ọ̀rọ̀ yìí.

Àwọn tí ó gbé ìròyìn náà jáde lo àwòrán Wike pẹ̀lú ọmọkùnrin kan tí ó wọ aṣọ asekagba/ìparí ẹ̀kọ́ tí àwọn akẹ́kọ̀ọ́ máa ń wọ (gaun giraduesọn).

Ayẹwo àwòrán náà tí a se ní orí ayélujára fi yé wa pé àwòrán náà kọ́kọ́ jáde ní orí ayélujára nínú osù keje, ọdún 2022.

Jordan Nyesom-Wike, son of the Rivers State Governor, Nyesom Wike has graduated from the University of Exeter, in the United Kingdom… pls can u see why they are not talking about ASUU strike. Well Congratulations pic.twitter.com/tFvFnmmKpQ

— Odinala Ndi IGBO (@enyinnayaibeka) July 11, 2022

Gẹ́gẹ́bí àkòrí àwòrán náà tí ìwé ìròyìn The Nation gbé jáde, wọ́n ya àwòrán náà nígbà tí Gómìnà náà àti àwọn ẹbí rẹ̀ lọ sí ibi ajọyọ ìparí ẹ̀kọ́ ọmọ rẹ̀ ọkùnrin, ẹni tí àwọn oniroyin ofege/irọ́ ní orí ayélujára sọ wí pé wọn yinbọn pa ní orílẹ̀-èdè Amẹ́ríkà.

Nígbà tí o sọ ọ̀rọ̀ nípa atẹjade yìí, Kelvin Ebiri, ẹni tí ó jẹ́ oluranlọwọ fún àwọn ọ̀rọ̀ orí ayélujára fún Gómìnà Wike sọ wí pé ọ̀rọ̀ yìí kìí se òtítọ́. Irọ́ ńlá gbáà ni.

Please send your feedback, claims to fact check and corrections requests to [email protected]

Yemi Michael March 9, 2023 March 9, 2023
Share this Article
Facebook Twitter Email Copy Link Print
Leave a comment Leave a comment

Leave a Reply Cancel reply

Your email address will not be published. Required fields are marked *

POPULAR POSTS

Advertisement

FACT CHECK: Video showing ‘bridge collapsing in Nasarawa’ is AI-generated

A video showing a bridge collapse incident is circulating across social media platforms, especially on…

July 24, 2025

MISINFO ALERT: Viral video of ‘foreign arms dealer’ in Zamfara is from 2021, says army

The Nigerian Army says a viral video claiming the arrest of a foreign arms dealer…

July 24, 2025

Ókwú Badenoch nà ụ́mụ̀ yá ápụ̀ghị̀ ínwétá íkíké ị́bụ ńdị́ Naijiria bụ̀ àsị́

Kemi Badenoch, onye ndú òtù Conservative Party nke obodo United Kingdom, ekwuola na ọ gaghị…

July 22, 2025

Kemi Badenoch claim sey her children no fit get Nigerian citizenship but she no tok true

Kemi Badenoch, leader of di United Kingdom Conservative Party, claim sey she no fit pass…

July 22, 2025
Advertisement
Advertisement

YOU MAY ALSO LIKE

Ókwú Badenoch nà ụ́mụ̀ yá ápụ̀ghị̀ ínwétá íkíké ị́bụ ńdị́ Naijiria bụ̀ àsị́

Kemi Badenoch, onye ndú òtù Conservative Party nke obodo United Kingdom, ekwuola na ọ gaghị enyenwu ụmụ ya ikike ịbụ…

CHECK AM FOR WAZOBIA
July 22, 2025

Kemi Badenoch claim sey her children no fit get Nigerian citizenship but she no tok true

Kemi Badenoch, leader of di United Kingdom Conservative Party, claim sey she no fit pass her right of Nigerian citizenship…

CHECK AM FOR WAZOBIA
July 22, 2025

Irọ́ ni Kemi Badenoch pa pé òfin kò fààyè gba àwọn ọmọ òhun láti di ọmọ Nàìjíríà

Kemi Badenoch, arábìnrin tó jẹ́ olórí ẹgbẹ́ òsèlú alátakò tí wọ́n ń pè ní Conservative Party ní orílẹ̀ èdè United…

CHECK AM FOR WAZOBIA
July 22, 2025

Maganar Kemi Badenoch na cewa ‘ya’yanta ba za su iya samun shaidar zama dan Najeriya ba karya ne

Kemi Badenoch, shugabar jam'iyyar masu ra'ayin rikau ta Burtaniya, ta yi ikirarin cewa ba za ta iya mika hakkinta na…

CHECK AM FOR WAZOBIA
July 22, 2025

CableCheck seeks to provide reliable tools and resources for readers to tackle the menace of fake and misleading materials constantly pushed into the public space from various sources. We monitor the accuracy of claims made in traditional and social media. We also provide a tracker to hold politicians and policymakers accountable for the plans and promises they make to the public. CableCheck is a project of the Cable Newspaper Journalism Foundation (CNJF), supported by the MacArthur Foundation and implemented by TheCable newspaper.

Follow US: 

LINKS

  • Contact
  • About Us
  • Non-Partisanship Policy
  • Funding
  • Correction Policy
© Copyright TheCable. All Rights reserved.
Welcome Back!

Sign in to your account

Lost your password?