TheCable Fact Check
  • Home
  • Fact Check
  • Fake News
  • Check Am For Wazobia
Reading: Rárá, Jonathan kò sọ pé Tinubu yóò se àṣeyọrí nínú ètò ìdìbò fún Ipò Ààrẹ ní ọdún 2027
Share
Latest News
FACT CHECK: Viral image depicting ‘Obasanjo prostrating for Ladoja’ photoshopped
Wike tụ̀rụ̀ àsị́. Peter Obi mèrè ńtụ̀líáká ọ̀chị́chị́ ḿpághárá m̀gbè ọ́ bụ̀ gọ́vánọ̀ Anambra
Irọ́ ni Wike pa. Peter Obi ṣètò ìdìbò ìjọba ìbílẹ̀ nígbà tí ó jẹ́ gómìnà Ìpínlẹ̀ Anambra
Wike yayi kuskure. Peter Obi ya gudanar da zaben LG a matsayin gwamnan Anambra
Wike make mistake. Peter Obi conduct LG election as Anambra governor
Video wey show as Thomas Partey dey blame ‘rape’ case on racism na fake
Bidiyon da ke nuna Partey yana zargin shari’ar ‘fyade’ akan wariyar launin fata da aka gyara ta hanyar lambobi
AI ni fídíò tí ó fi ẹ̀sùn ìbánifipálòpọ̀ kan Thomas Partey
Advertisement
Aa
TheCable Fact CheckTheCable Fact Check
Search
  • Home
  • Fact Check
  • Fake News
  • Check Am For Wazobia
Follow US

Rárá, Jonathan kò sọ pé Tinubu yóò se àṣeyọrí nínú ètò ìdìbò fún Ipò Ààrẹ ní ọdún 2027

Yemi Michael
By Yemi Michael Published April 20, 2025 3 Min Read
Share

Ní ọjọ́ ajé, ọ̀rọ̀ kan to sọ pé Goodluck Jonathan, Ààrẹ orílẹ̀ èdè Nàìjíríà tẹ́lẹ̀ sọ pé Ààrẹ Bọla Tinubu yóò se àṣeyọrí ní ìgbà ìdìbò fún Ipò Ààrẹ ní ọdún 2027 ti di ohun tí àwọn ènìyàn ti ń pín kiri lórí ayélujára.

Ọ̀rọ̀ tó lè má jẹ́ òtítọ́ yìí sọ pé ìwé ìròyìn Daily Post ló gbé ọ̀rọ̀ yìí jáde ní ọjọ́ kẹẹdogun, oṣù kẹrin, ọdún 2025. Àwọn ènìyàn ti pín ọ̀rọ̀ yìí lọpọlọpọ ìgbà lórí Facebook, oun ibaraẹnise ìgbàlódé tí ó ní ọ̀pọ̀lọpọ̀ àwọn ènìyàn tí wọ́n ń tẹ̀lée. Ọ̀pọ̀lọpọ̀ àwọn ènìyàn sọ̀rọ̀ nípa ọ̀rọ̀ yìí, wọ́n sì tún pín ín lórí Tiktok, ohun ìgbàlódé ibaraẹnise tí àwọn ènìyàn ti máa ń fi àwòrán síta. Ẹ lè rí ọ̀rọ̀ yìí kà níbí àti níbí.

AYẸWO Ọ̀RỌ̀ YÌÍ TÍ CABLECHECK SE RÈÉ 

Nígbà tí CableCheck, ti TheCable Newspaper, se àyẹ̀wò àwọn ìròyìn Daily Post, ìwé ìròyìn tí àwọn ènìyàn ní ó gbé ọ̀rọ̀ yìí jáde, a ríi pé ìwé ìròyìn yìí kò gbé ìròyìn báyìí jáde. Nígbà tí a tún se àyẹ̀wò orí ayélujára ti Daily Post máa ń fi iroyin tó ti pẹ sí, a kò rí ohun tí ó jọ pé Jonathan sọ ọ̀rọ̀ báyìí.

Ní àfikún, àwòrán tí ó wà nínú ọ̀rọ̀ yìí lórí Facebook yàtọ̀ sí bí lẹ́tà àwọn ọ̀rọ̀ ìròyìn Daily Post ṣe máa ń rí tàbí tó, èyí tí ó túmọ̀ sí pé àwọn ènìyàn tí wọ́n fi ọ̀rọ̀ yìí síta lórí Facebook dá ọgbọ́n lọ́nà tí kò yẹ sí ọ̀rọ̀ yìí ní.

A tún ríi pé kò sí ilé isẹ ìròyìn tí ó ṣeé gbára lé tó sọ pé Jonathan sọ irú ọ̀rọ̀ yìí.

CableCheck kàn sí àwọn ènìyàn tí wọ́n ń bá Jonathan rí sí ọ̀rọ̀ ìròyìn láti lè mọ̀ bóyá òótọ́ ni ọ̀rọ̀ yìí. Ikechukwu Eze, olúrànlọ́wọ́ Jonathan sọ pé ọ̀rọ̀ yìí kìí se òótọ́.

Eze sọ pé kò sí ìgbà kankan tí Jonathan bá onisẹ ìròyìn kankan sọ irú ọ̀rọ̀ báyìí lórí ètò ìdìbò fún Ipò Ààrẹ ni ọdún 2027.

BÍ A SE RÍ Ọ̀RỌ̀ YÌÍ ṢÍ 

Jonathan kò sọ irú ọ̀rọ̀ báyìí. Irọ ni.

TAGGED: 2027 Election, Bola Tinubu, factcheck, Factcheck in Yorùbá, Goodluck Jonathan, News in Yorùbá

Please send your feedback, claims to fact check and corrections requests to [email protected]

Yemi Michael April 20, 2025 April 20, 2025
Share this Article
Facebook Twitter Email Copy Link Print

POPULAR POSTS

Advertisement

FACT CHECK: Viral image depicting ‘Obasanjo prostrating for Ladoja’ photoshopped

An image showing a person prostrating for Rashidi Ladoja, the Olubadan-in-waiting and former governor of…

July 11, 2025

Wike tụ̀rụ̀ àsị́. Peter Obi mèrè ńtụ̀líáká ọ̀chị́chị́ ḿpághárá m̀gbè ọ́ bụ̀ gọ́vánọ̀ Anambra

Nyesom Wike, onye minista nke isi obodo Naijiria bụ FCT, kwuru na Peter Obi, onye…

July 11, 2025

Irọ́ ni Wike pa. Peter Obi ṣètò ìdìbò ìjọba ìbílẹ̀ nígbà tí ó jẹ́ gómìnà Ìpínlẹ̀ Anambra

Nyesom Wike, minisita fún Federal Capital Territory (FCT), Abuja, olú ìlú orílẹ̀ èdè Nàìjíríà, sọ…

July 11, 2025

Wike yayi kuskure. Peter Obi ya gudanar da zaben LG a matsayin gwamnan Anambra

Nyesom Wike, ministan babban birnin tarayya Abuja, ya ce Peter Obi, tsohon gwamnan Anambra kuma…

July 11, 2025
Advertisement
Advertisement

YOU MAY ALSO LIKE

Wike tụ̀rụ̀ àsị́. Peter Obi mèrè ńtụ̀líáká ọ̀chị́chị́ ḿpághárá m̀gbè ọ́ bụ̀ gọ́vánọ̀ Anambra

Nyesom Wike, onye minista nke isi obodo Naijiria bụ FCT, kwuru na Peter Obi, onye bụ buru gọvanọ Anambra steetị…

CHECK AM FOR WAZOBIA
July 11, 2025

Irọ́ ni Wike pa. Peter Obi ṣètò ìdìbò ìjọba ìbílẹ̀ nígbà tí ó jẹ́ gómìnà Ìpínlẹ̀ Anambra

Nyesom Wike, minisita fún Federal Capital Territory (FCT), Abuja, olú ìlú orílẹ̀ èdè Nàìjíríà, sọ pé Peter Obi, ẹni tí…

CHECK AM FOR WAZOBIA
July 11, 2025

Wike yayi kuskure. Peter Obi ya gudanar da zaben LG a matsayin gwamnan Anambra

Nyesom Wike, ministan babban birnin tarayya Abuja, ya ce Peter Obi, tsohon gwamnan Anambra kuma dan takarar shugaban kasa na…

CHECK AM FOR WAZOBIA
July 11, 2025

Wike make mistake. Peter Obi conduct LG election as Anambra governor

Nyesom Wike, minister of di Federal Capital Territory (FCT), tok sey Peter Obi, forma govnor of Anambra and 2023 Labour…

CHECK AM FOR WAZOBIA
July 11, 2025

CableCheck seeks to provide reliable tools and resources for readers to tackle the menace of fake and misleading materials constantly pushed into the public space from various sources. We monitor the accuracy of claims made in traditional and social media. We also provide a tracker to hold politicians and policymakers accountable for the plans and promises they make to the public. CableCheck is a project of the Cable Newspaper Journalism Foundation (CNJF), supported by the MacArthur Foundation and implemented by TheCable newspaper.

Follow US: 

LINKS

  • Contact
  • About Us
  • Non-Partisanship Policy
  • Funding
  • Correction Policy
© Copyright TheCable. All Rights reserved.
Welcome Back!

Sign in to your account

Lost your password?