TheCable Fact Check
  • Home
  • Fact Check
  • Fake News
  • Check Am For Wazobia
Reading: Rárá, Jonathan kò sọ pé Tinubu yóò se àṣeyọrí nínú ètò ìdìbò fún Ipò Ààrẹ ní ọdún 2027
Share
Latest News
FACT CHECK: Video attributed to ‘security operatives’ breaking into apartment isn’t from south-east
FAKE NEWS ALERT: WAEC denies viral list showing schools affected by results cancellation
Ḿbà, Nwifuru àkwụ́sịghị́ ńdị́ kọ̀mị́shọnà ya ọ́rụ́ màkà nà há ábịaghị ńchètá ọ̀mụ́mụ́ nwá ya
No, Nwifuru no suspend officials becos dem no gree attend im pikin birthday party
Nwifuru kò dá àwọn òṣìṣẹ́ dúró lẹ́nu iṣẹ́ nítorí pé wọ́n kò wá sí ibi ayẹyẹ ọjọ́ ìbí ọmọ rẹ̀
A’a, Nwifuru bai dakatar da jami’ai ba saboda rashin halartar bikin ranar haihuwar yaro
Video wey show as ‘bridge collapse for Nasarawa’ na AI
AI ni wọ́n fi se fídíò afárá ti wọ́n ní ó wó ní Nasarawa
Advertisement
Aa
TheCable Fact CheckTheCable Fact Check
Search
  • Home
  • Fact Check
  • Fake News
  • Check Am For Wazobia
Follow US

Rárá, Jonathan kò sọ pé Tinubu yóò se àṣeyọrí nínú ètò ìdìbò fún Ipò Ààrẹ ní ọdún 2027

Yemi Michael
By Yemi Michael Published April 20, 2025 3 Min Read
Share

Ní ọjọ́ ajé, ọ̀rọ̀ kan to sọ pé Goodluck Jonathan, Ààrẹ orílẹ̀ èdè Nàìjíríà tẹ́lẹ̀ sọ pé Ààrẹ Bọla Tinubu yóò se àṣeyọrí ní ìgbà ìdìbò fún Ipò Ààrẹ ní ọdún 2027 ti di ohun tí àwọn ènìyàn ti ń pín kiri lórí ayélujára.

Ọ̀rọ̀ tó lè má jẹ́ òtítọ́ yìí sọ pé ìwé ìròyìn Daily Post ló gbé ọ̀rọ̀ yìí jáde ní ọjọ́ kẹẹdogun, oṣù kẹrin, ọdún 2025. Àwọn ènìyàn ti pín ọ̀rọ̀ yìí lọpọlọpọ ìgbà lórí Facebook, oun ibaraẹnise ìgbàlódé tí ó ní ọ̀pọ̀lọpọ̀ àwọn ènìyàn tí wọ́n ń tẹ̀lée. Ọ̀pọ̀lọpọ̀ àwọn ènìyàn sọ̀rọ̀ nípa ọ̀rọ̀ yìí, wọ́n sì tún pín ín lórí Tiktok, ohun ìgbàlódé ibaraẹnise tí àwọn ènìyàn ti máa ń fi àwòrán síta. Ẹ lè rí ọ̀rọ̀ yìí kà níbí àti níbí.

AYẸWO Ọ̀RỌ̀ YÌÍ TÍ CABLECHECK SE RÈÉ 

Nígbà tí CableCheck, ti TheCable Newspaper, se àyẹ̀wò àwọn ìròyìn Daily Post, ìwé ìròyìn tí àwọn ènìyàn ní ó gbé ọ̀rọ̀ yìí jáde, a ríi pé ìwé ìròyìn yìí kò gbé ìròyìn báyìí jáde. Nígbà tí a tún se àyẹ̀wò orí ayélujára ti Daily Post máa ń fi iroyin tó ti pẹ sí, a kò rí ohun tí ó jọ pé Jonathan sọ ọ̀rọ̀ báyìí.

Ní àfikún, àwòrán tí ó wà nínú ọ̀rọ̀ yìí lórí Facebook yàtọ̀ sí bí lẹ́tà àwọn ọ̀rọ̀ ìròyìn Daily Post ṣe máa ń rí tàbí tó, èyí tí ó túmọ̀ sí pé àwọn ènìyàn tí wọ́n fi ọ̀rọ̀ yìí síta lórí Facebook dá ọgbọ́n lọ́nà tí kò yẹ sí ọ̀rọ̀ yìí ní.

A tún ríi pé kò sí ilé isẹ ìròyìn tí ó ṣeé gbára lé tó sọ pé Jonathan sọ irú ọ̀rọ̀ yìí.

CableCheck kàn sí àwọn ènìyàn tí wọ́n ń bá Jonathan rí sí ọ̀rọ̀ ìròyìn láti lè mọ̀ bóyá òótọ́ ni ọ̀rọ̀ yìí. Ikechukwu Eze, olúrànlọ́wọ́ Jonathan sọ pé ọ̀rọ̀ yìí kìí se òótọ́.

Eze sọ pé kò sí ìgbà kankan tí Jonathan bá onisẹ ìròyìn kankan sọ irú ọ̀rọ̀ báyìí lórí ètò ìdìbò fún Ipò Ààrẹ ni ọdún 2027.

BÍ A SE RÍ Ọ̀RỌ̀ YÌÍ ṢÍ 

Jonathan kò sọ irú ọ̀rọ̀ báyìí. Irọ ni.

TAGGED: 2027 Election, Bola Tinubu, factcheck, Factcheck in Yorùbá, Goodluck Jonathan, News in Yorùbá

Please send your feedback, claims to fact check and corrections requests to [email protected]

Yemi Michael April 20, 2025 April 20, 2025
Share this Article
Facebook Twitter Email Copy Link Print

POPULAR POSTS

Advertisement

FACT CHECK: Video attributed to ‘security operatives’ breaking into apartment isn’t from south-east

A Facebook user has claimed that a video showing hooded armed security operatives breaking into…

August 5, 2025

FAKE NEWS ALERT: WAEC denies viral list showing schools affected by results cancellation

The West African Examinations Council (WAEC) has dismissed a viral list which claimed that results…

August 5, 2025

Ḿbà, Nwifuru àkwụ́sịghị́ ńdị́ kọ̀mị́shọnà ya ọ́rụ́ màkà nà há ábịaghị ńchètá ọ̀mụ́mụ́ nwá ya

Ótù ozi na shoshal midia ekwuola na Francis Nwifuru, gọvanọ Ebonyi steeti, kwụsịrị ndị komịshọna…

August 1, 2025

No, Nwifuru no suspend officials becos dem no gree attend im pikin birthday party

One social media post claim sey Francis Nwifuru, govnor of Ebonyi, suspend 25 commissioners and…

August 1, 2025
Advertisement
Advertisement

YOU MAY ALSO LIKE

Ḿbà, Nwifuru àkwụ́sịghị́ ńdị́ kọ̀mị́shọnà ya ọ́rụ́ màkà nà há ábịaghị ńchètá ọ̀mụ́mụ́ nwá ya

Ótù ozi na shoshal midia ekwuola na Francis Nwifuru, gọvanọ Ebonyi steeti, kwụsịrị ndị komịshọna iri abụọ n'ise (25 commissioners)…

CHECK AM FOR WAZOBIA
August 1, 2025

No, Nwifuru no suspend officials becos dem no gree attend im pikin birthday party

One social media post claim sey Francis Nwifuru, govnor of Ebonyi, suspend 25 commissioners and oda appointees becos dem no…

CHECK AM FOR WAZOBIA
August 1, 2025

Nwifuru kò dá àwọn òṣìṣẹ́ dúró lẹ́nu iṣẹ́ nítorí pé wọ́n kò wá sí ibi ayẹyẹ ọjọ́ ìbí ọmọ rẹ̀

Ọ̀rọ̀ kan lórí ohun ìgbàlódé íbaraẹnise orí ayélujára sọ pé Francis Nwifuru, gómìnà Ìpínlẹ̀ Ebonyi dá àwọn kọmisọnna marundinlọgbọn àti…

CHECK AM FOR WAZOBIA
August 1, 2025

A’a, Nwifuru bai dakatar da jami’ai ba saboda rashin halartar bikin ranar haihuwar yaro

Wani rubutu da aka wallafa a dandalin sada zumunta ya yi ikirarin cewa Francis Nwifuru, gwamnan Ebonyi, ya dakatar da…

CHECK AM FOR WAZOBIA
August 1, 2025

CableCheck seeks to provide reliable tools and resources for readers to tackle the menace of fake and misleading materials constantly pushed into the public space from various sources. We monitor the accuracy of claims made in traditional and social media. We also provide a tracker to hold politicians and policymakers accountable for the plans and promises they make to the public. CableCheck is a project of the Cable Newspaper Journalism Foundation (CNJF), supported by the MacArthur Foundation and implemented by TheCable newspaper.

Follow US: 

LINKS

  • Contact
  • About Us
  • Non-Partisanship Policy
  • Funding
  • Correction Policy
© Copyright TheCable. All Rights reserved.
Welcome Back!

Sign in to your account

Lost your password?