TheCable Fact Check
  • Home
  • Fact Check
  • Fake News
  • Check Am For Wazobia
Reading: Ìròyìn Ẹlẹ́jẹ̀: Ilé-ẹjọ́ ọ fagile èsì ìbò abẹ́nú APC ní Èkìtì
Share
Latest News
Rárá, Nàìjíríà kò fi àwọn ọmọ iṣẹ́ ológun rán sẹ sí Ísírẹ́lì láti dá rògbòdìyàn tó ń ṣẹlẹ̀ níbẹ̀ dúró
Ḿbà, Naijiria ézipụ̀ghị̀ ńdị́ ágha ńkwàdó ùdó nà òbòdò Isreal
No, Nigeria no send peace support mission go Israel
A’a, Najeriya ba ta tura tawagar taimakon zaman lafiya zuwa Isra’ila ba
Ǹjẹ́ Tinubu àti Alexander Zingman lọ sí ilé-ìwé kan náà? Èyí ni ohun tí a mọ̀
Tinubu nà Alexander Zingman ọ̀ gàrà ótù ụ́lọ̀ákwụ́kwọ́? Lèé íhé ányị́ mà
Tinubu go di same school wit Alexander Zingman? Na wetin we sabi be dis
Shin Tinubu ya halarci makaranta daya da Alexander Zingman? Ga abin da muka sani
Advertisement
Aa
TheCable Fact CheckTheCable Fact Check
Search
  • Home
  • Fact Check
  • Fake News
  • Check Am For Wazobia
Follow US

Ìròyìn Ẹlẹ́jẹ̀: Ilé-ẹjọ́ ọ fagile èsì ìbò abẹ́nú APC ní Èkìtì

Elizabeth Ogunbamowo
By Elizabeth Ogunbamowo Published June 18, 2022 4 Min Read
Share

Ilé ẹjọ́ gíga ti ìjọba àpapọ̀ ìlú Abuja ò jòkó ni ọjọ́bọ̀ lórí ìbò abẹ́nú ti egbé òsèlú All Progressives Congress ní Ìpínlè Èkìtì.

Ìròyìn tán ràn-ìn lórí ayélujára pé ilé ẹjọ́ gíga Abuja fagilé ìbò abẹ́nú ẹgbẹ́ òsèlú APC ní Èkìtì, èyí sí túmọ sí wípé Bíọ́dún Oyèbanji, olùdíje ẹgbẹ́ náà, kò ní kópa nínú ìdìbò òún.

Ọjọ kejìdínlógún oṣù kẹfà ní ìdìbò gómìnà Èkìtì yóò wáyé.

Àyẹwò TheCable fihàn wípé kò sí irúfé ìjòkó bẹẹ ní Ọjọ́bọ̀.

Catherine Oby-Christopher, ẹni tí ó jẹ amugbalẹgbẹ olùdarí fún ìròyìn ní Ilé ẹjọ́ gíga ti ìjọba àpapọ̀, sọ nínú àtẹ̀jáde kàn wípé irọ́ ni èyí.

“Ilé ẹjọ́ gíga ti ìjọba àpapọ̀ ti rí ìròyìn tí ó ń tàn ká’lé ká’ko lórí àkòrí yìí pelu suit nọmbà FHC/ABJ/CS/528/22, pé Adájọ́ àgbà Inyang Ekwo ṣe ìdájọ́ wípé Biodun Oyebanji, kòlè kópa nínú ìdìbò gómìnà Èkìtì, ní wákàtí díẹ̀ sí ìdíje náà,” àtẹ̀jáde yìí wí.

“Kò sí oun tó jọ bẹ́ẹ̀. Kódà kò sí ẹjọ́ kan-kan tó tan mọ́ ọ̀rọ̀ náà ní sàkání agbára ilé ẹjọ́ yìí.

“Ilé ẹjọ́ yìí fi ìdí rẹ̀ múlẹ̀ pé a kò gbé irúfẹ́ ẹjọ́ báyìí wá síwájú Adájọ àgbà I.E. Ekwo.

“Ìròyìn òfégè ni ìròyìn yìí, wọ́n sì fẹ fí tan ará ìlú jẹ ní, kí o sí dá rògbòdìyàn ati àìbalẹ̀ ọkàn.

“Ìròyìn ẹlẹ́jẹ̀ yìí burú jái, a sì lòdì síi pẹ̀lú. Arọ àwọn ará ìlú kí wọn má ṣe f’ọkan síi.

Segun Dipe, agbẹnusọ ẹgbẹ́ òṣèlú APC ní ìlú Ekiti sọ pé ìrọ́ tó jìnà sí òtítọ́ ni ìròyìn náà, ofi kun wípé bótilè jẹ́ wípé oríṣi ẹjọ́ ló wà níwájú ilé ẹjọ́ káàkiri, kò sí èyí tí ó ti kọjá ipele àkọ́kọ́.

“Ìròyìn ẹlẹ́jẹ̀ náà jẹ ète àwọn ẹgbẹ́ alátakò tí wọ́n kò mọ̀ wípé ète yìí yóò mú àbùkù bá wọn ní inú ìdíje náà.

“Bótilẹ̀ jẹ́ wípé kò yẹ ki ẹnikẹni f’ọkan sí ìròyìn yìí, ojúṣe wa ni láti sọ fún àwọn ènìyàn kí wọn má ṣe kọbiarasi ìròyìn tó jìnà sí òótọ́ yìí.

“Looto, awọn kan fí esun le’lẹ nípa ìdìbò abẹ́lé ti o waye ni oṣù kínní tí Biodun Abayomi Oyebanji sí ṣe Olubori nínú re party, àmọ́, àwọn ẹjọ́ yìí ò kọjá ipele àkọ́kọ́, wọ́n sì ti gbé àwọn ẹjọ́ yìí lọ sí Ekiti fún igbẹ́jọ́.

“Kò sí ilé ẹjọ́ gíga kan-kan ti o jòkó lórí ìdìbò abẹ́lé wa ni Abuja lónìí. Pẹ̀lú pẹ̀lú, ilé ẹjọ́ ti sún gbogbo igbẹ́jọ́ nípa ọ̀rọ̀ ìdìbò abẹ́lé wa sí Ọwẹ́wẹ̀, ọdún yìí. Kò sí ẹ̀yí tí igbẹ́jọ́ rẹ̀ ń wáyé lásìkò yìí. Gbogbo akitiyan ẹgbẹ́ òṣèlú wa ni kí a ṣe àṣeyọrí nínú ìdìbò yìí.

“Wàyí Egbẹ́ òsèlú APC ń sọ fún gbogbo olùdibò ní Ìpínlè Èkìtì kí wọ́n f’ọkàn balẹ̀, kí wọn sì má ṣe ojo nínú ìpinu wọn láti dìbò fún àyànfẹ olùdíje, Oyebanji àti ẹgbẹ́ òṣèlú APC ní ọjọ́ àbámẹ́ta, ọjọ́ kejìdínlógún, oṣù kẹfà, ọdún 2022.”

 

A kọ ìròyìn yìí ni ajọṣepọ pẹlu Report for the World, eto agbaye ti o ṣe atilẹyin iṣẹ iroyin tiwa-n-tiwa.

TAGGED: APC, Biodun Oyebanji, Ekiti

Please send your feedback, claims to fact check and corrections requests to [email protected]

Elizabeth Ogunbamowo June 18, 2022 June 18, 2022
Share this Article
Facebook Twitter Email Copy Link Print
Leave a comment Leave a comment

Leave a Reply Cancel reply

Your email address will not be published. Required fields are marked *

POPULAR POSTS

Advertisement

Rárá, Nàìjíríà kò fi àwọn ọmọ iṣẹ́ ológun rán sẹ sí Ísírẹ́lì láti dá rògbòdìyàn tó ń ṣẹlẹ̀ níbẹ̀ dúró

Ìròyìn lati inú fídíò Facebook kan sọ pé Nàìjíríà fi àwọn ọmọ ogun ránṣẹ́ sí…

June 28, 2025

Ḿbà, Naijiria ézipụ̀ghị̀ ńdị́ ágha ńkwàdó ùdó nà òbòdò Isreal

Ótù ihe ngosị si na Facebook kwuru na Naijiria zipụrụ ndị agha ka ha gaa…

June 28, 2025

No, Nigeria no send peace support mission go Israel

One Facebook video claim sey Nigeria send soldiers go Israel for joint peace support mission.…

June 28, 2025

A’a, Najeriya ba ta tura tawagar taimakon zaman lafiya zuwa Isra’ila ba

Wani faifan bidiyo na Facebook ya nuna cewa Najeriya ta tura dakaru domin aikin hadin…

June 28, 2025
Advertisement
Advertisement

YOU MAY ALSO LIKE

Rárá, Nàìjíríà kò fi àwọn ọmọ iṣẹ́ ológun rán sẹ sí Ísírẹ́lì láti dá rògbòdìyàn tó ń ṣẹlẹ̀ níbẹ̀ dúró

Ìròyìn lati inú fídíò Facebook kan sọ pé Nàìjíríà fi àwọn ọmọ ogun ránṣẹ́ sí orílẹ̀ èdè Ísírẹ́lì kí rògbòdìyàn…

CHECK AM FOR WAZOBIA
June 28, 2025

Ḿbà, Naijiria ézipụ̀ghị̀ ńdị́ ágha ńkwàdó ùdó nà òbòdò Isreal

Ótù ihe ngosị si na Facebook kwuru na Naijiria zipụrụ ndị agha ka ha gaa kwàdó udo na mba Isreal.…

CHECK AM FOR WAZOBIA
June 28, 2025

No, Nigeria no send peace support mission go Israel

One Facebook video claim sey Nigeria send soldiers go Israel for joint peace support mission. One male broadcaster wey dey…

CHECK AM FOR WAZOBIA
June 28, 2025

A’a, Najeriya ba ta tura tawagar taimakon zaman lafiya zuwa Isra’ila ba

Wani faifan bidiyo na Facebook ya nuna cewa Najeriya ta tura dakaru domin aikin hadin gwiwa na tallafawa zaman lafiya…

CHECK AM FOR WAZOBIA
June 28, 2025

CableCheck seeks to provide reliable tools and resources for readers to tackle the menace of fake and misleading materials constantly pushed into the public space from various sources. We monitor the accuracy of claims made in traditional and social media. We also provide a tracker to hold politicians and policymakers accountable for the plans and promises they make to the public. CableCheck is a project of the Cable Newspaper Journalism Foundation (CNJF), supported by the MacArthur Foundation and implemented by TheCable newspaper.

Follow US: 

LINKS

  • Contact
  • About Us
  • Non-Partisanship Policy
  • Funding
  • Correction Policy
© Copyright TheCable. All Rights reserved.
Welcome Back!

Sign in to your account

Lost your password?