TheCable Fact Check
  • Home
  • Fact Check
  • Fake News
  • Check Am For Wazobia
Reading: Ǹjẹ́ òtítọ́ ni pé Ìpínlẹ̀ Nasarawa kò tíì yá owó láti ìgbà tí Tinubu ti di ààrẹ?
Share
Latest News
FACT CHECK: Video attributed to ‘security operatives’ breaking into apartment isn’t from south-east
FAKE NEWS ALERT: WAEC denies viral list showing schools affected by results cancellation
Ḿbà, Nwifuru àkwụ́sịghị́ ńdị́ kọ̀mị́shọnà ya ọ́rụ́ màkà nà há ábịaghị ńchètá ọ̀mụ́mụ́ nwá ya
No, Nwifuru no suspend officials becos dem no gree attend im pikin birthday party
Nwifuru kò dá àwọn òṣìṣẹ́ dúró lẹ́nu iṣẹ́ nítorí pé wọ́n kò wá sí ibi ayẹyẹ ọjọ́ ìbí ọmọ rẹ̀
A’a, Nwifuru bai dakatar da jami’ai ba saboda rashin halartar bikin ranar haihuwar yaro
Video wey show as ‘bridge collapse for Nasarawa’ na AI
AI ni wọ́n fi se fídíò afárá ti wọ́n ní ó wó ní Nasarawa
Advertisement
Aa
TheCable Fact CheckTheCable Fact Check
Search
  • Home
  • Fact Check
  • Fake News
  • Check Am For Wazobia
Follow US

Ǹjẹ́ òtítọ́ ni pé Ìpínlẹ̀ Nasarawa kò tíì yá owó láti ìgbà tí Tinubu ti di ààrẹ?

Yemi Michael
By Yemi Michael Published December 10, 2024 4 Min Read
Share

Ní ọjọ́ Ajé, Abdullahi Sule, gómìnà Ìpínlẹ̀ Nasarawa sọ pé Ìpínlẹ̀ òhun kò yá owó kankan láti ìgbà tí Bọlá Tinubu ti di aàrẹ Nàìjíríà.

Sule sọ ọ̀rọ̀ yìí nígbà tí ó se ìpàdé pẹ̀lú àwọn ara Ìpínlẹ̀ Nasarawa, èyí tí ilé isẹ amohunmaworan tí a mọ̀ sí Channels Television ṣe agbekalẹ rẹ̀.

“Mo gbọ pé ẹni kan sọ pé láti ìgbà tí Ààrẹ Tinubu tí di olórí, owó tí ó ń wọlé sí àpò àwọn Ìpínlẹ̀ ti lé síi, àwọn sì fẹ́ mọ ohun tí wọ́n ń fi àwọn owó yìí ṣe,” gómìnà yìí ló sọ báyìí.

“Ẹ lọ sí àwọn àwọn Ìpínlẹ̀, ẹ máa rí àwọn nǹkan tí àwọn gómìnà ń fi àwọn owó yìí se.

“Ní Ìpínlẹ̀ Nasarawa, n kò tí ì yá owó kankan láti ìgbà tí Tinubu ti di Ààrẹ, mo sì lè fọwọ́ sọ̀yà pé a ní ilẹ̀ bíi ẹgbẹ̀rún mẹwa hẹkita tí a fi ń ṣe àgbẹ̀. A sì ti san gbogbo àwọn ohun tí a ń lò, mo lè máa sọrọ síwájú síi.

AYẸWO 

Àwọn ọmọ Nàìjíríà fi ìbò yàn Tinubu gẹ́gẹ́bí Ààrẹ ní oṣù kejì, ọdún 2023, wọ́n sì búra fún un ní ọjọ́ kọkàndínlógún, oṣù karùn-ún, ọdún 2023.

Láti lè se àyẹ̀wò ọ̀rọ̀ yìí, TheCable, ìwé ìròyìn orí ayélujára ṣàyẹ̀wò gbèsè owó tí àwọn Ìpínlẹ̀ jẹ àwọn ayanilowo ní Nàìjíríà àti àwọn orílẹ̀ èdè mìíràn lórí ohun ayélujára tí Debt Management Office (DMO) se agbekalẹ rẹ̀ láti ìgbà tí Tinubu ti di Ààrẹ sí àsìkò yìí.

GBÈSÈ OWÓ TÍ NASARAWA JẸ 

Ní oṣù kẹfà, ọdún 2023, oṣù kan lẹ́hìn ìgbà tí Tinubu di Ààrẹ, DMO sọ pé gbèsè owó tí Nasarawa jẹ́ àwọn ayanilowo ní Nàìjíríà jẹ́ biliọnu mọkanlelaadọrin ó lé ní ọ̀pọ̀lọpọ̀ mílíọ̀nù naira.

Nasarawa’s domestic debt as of June 2023

Ní oṣù kẹfà, ọdún 2024, gbèsè yìí lọ silẹ, ó di biliọnu mẹtalelogun àti ẹẹdẹgbẹrun ó lé ogójì miliọnu náírà. Èyí túmọ̀ sí pé ìdá ọgọ́ta àti bíi mẹ́fà ni gbèsè Nasarawa fi lọ silẹ sí ìyè gbèsè ìgbà tí Tinubu di Ààrẹ.

Nasarawa’s domestic debt as of June 2024

GBÈSÈ OWÓ TÍ NASARAWA JẸ ÀWỌN AYANILOWO NÍ ÀWỌN ORÍLẸ̀ ÈDÈ MÌÍRÀN

Nígbà tí TheCable se àyẹ̀wò ṣíwájú nípa gbèsè tí Nasarawa jẹ, a ríi pé gbèsè náà ti di mílíọ̀nù mejilelaaadọta ó lé  pupọ ni owó dọ́là ní oṣù kẹfà, ọdún 2023.

Nasarawa’s external debt as of June 2023

Nígbà tí a tún se àyẹ̀wò ṣíwájú síi, a ríi pé iye tí gbèsè yìí jẹ́ ní oṣù kẹfà, ọdún 2024 ju iye ti ó jẹ́ ní oṣù kẹfà, ọdún 2023.

Nasarawa’s external debt as of June 2024

BÍ A SE RÍ Ọ̀RỌ̀ YÌÍ ṢÍ

Ọ̀rọ̀ tí Sule sọ pé ìjọba òhun kò yá owó láti ìgbà tí Tinubu ti di Ààrẹ kìí se irọ.

TAGGED: Abdullahi Sule, debt, Fact Check, Fact check in Yoruba, Nasarawa state, News in Yorùbá

Please send your feedback, claims to fact check and corrections requests to [email protected]

Yemi Michael December 23, 2024 December 10, 2024
Share this Article
Facebook Twitter Email Copy Link Print
Leave a comment Leave a comment

Leave a Reply Cancel reply

Your email address will not be published. Required fields are marked *

POPULAR POSTS

Advertisement

FACT CHECK: Video attributed to ‘security operatives’ breaking into apartment isn’t from south-east

A Facebook user has claimed that a video showing hooded armed security operatives breaking into…

August 5, 2025

FAKE NEWS ALERT: WAEC denies viral list showing schools affected by results cancellation

The West African Examinations Council (WAEC) has dismissed a viral list which claimed that results…

August 5, 2025

Ḿbà, Nwifuru àkwụ́sịghị́ ńdị́ kọ̀mị́shọnà ya ọ́rụ́ màkà nà há ábịaghị ńchètá ọ̀mụ́mụ́ nwá ya

Ótù ozi na shoshal midia ekwuola na Francis Nwifuru, gọvanọ Ebonyi steeti, kwụsịrị ndị komịshọna…

August 1, 2025

No, Nwifuru no suspend officials becos dem no gree attend im pikin birthday party

One social media post claim sey Francis Nwifuru, govnor of Ebonyi, suspend 25 commissioners and…

August 1, 2025
Advertisement
Advertisement

YOU MAY ALSO LIKE

Ḿbà, Nwifuru àkwụ́sịghị́ ńdị́ kọ̀mị́shọnà ya ọ́rụ́ màkà nà há ábịaghị ńchètá ọ̀mụ́mụ́ nwá ya

Ótù ozi na shoshal midia ekwuola na Francis Nwifuru, gọvanọ Ebonyi steeti, kwụsịrị ndị komịshọna iri abụọ n'ise (25 commissioners)…

CHECK AM FOR WAZOBIA
August 1, 2025

No, Nwifuru no suspend officials becos dem no gree attend im pikin birthday party

One social media post claim sey Francis Nwifuru, govnor of Ebonyi, suspend 25 commissioners and oda appointees becos dem no…

CHECK AM FOR WAZOBIA
August 1, 2025

Nwifuru kò dá àwọn òṣìṣẹ́ dúró lẹ́nu iṣẹ́ nítorí pé wọ́n kò wá sí ibi ayẹyẹ ọjọ́ ìbí ọmọ rẹ̀

Ọ̀rọ̀ kan lórí ohun ìgbàlódé íbaraẹnise orí ayélujára sọ pé Francis Nwifuru, gómìnà Ìpínlẹ̀ Ebonyi dá àwọn kọmisọnna marundinlọgbọn àti…

CHECK AM FOR WAZOBIA
August 1, 2025

A’a, Nwifuru bai dakatar da jami’ai ba saboda rashin halartar bikin ranar haihuwar yaro

Wani rubutu da aka wallafa a dandalin sada zumunta ya yi ikirarin cewa Francis Nwifuru, gwamnan Ebonyi, ya dakatar da…

CHECK AM FOR WAZOBIA
August 1, 2025

CableCheck seeks to provide reliable tools and resources for readers to tackle the menace of fake and misleading materials constantly pushed into the public space from various sources. We monitor the accuracy of claims made in traditional and social media. We also provide a tracker to hold politicians and policymakers accountable for the plans and promises they make to the public. CableCheck is a project of the Cable Newspaper Journalism Foundation (CNJF), supported by the MacArthur Foundation and implemented by TheCable newspaper.

Follow US: 

LINKS

  • Contact
  • About Us
  • Non-Partisanship Policy
  • Funding
  • Correction Policy
© Copyright TheCable. All Rights reserved.
Welcome Back!

Sign in to your account

Lost your password?