TheCable Fact Check
  • Home
  • Fact Check
  • Fake News
  • Check Am For Wazobia
Reading: Wọn kò yin ìbọn pá ọmọkùnrin kan soso tí Wike bí ní orílẹ̀-èdè Amẹ́ríkà
Share
Latest News
Video wey tok sey Nigerian church dey on fire na lie, na Ghana school
Ị́hé ńgósị́ ụ́lọ́ákwụ́kwọ́ Ghana gbáráọ́kụ́ ká á sị́ n’ọ́bụ́ ụ́lọ́ ụ́ká dị́ nà Naijiria
Bidiyon gobarar da ta faru a makarantar Ghana da aka bayyana karya a matsayin kona cocin Najeriya
Ghana ni ìṣẹ̀lẹ iná ní ilé ìwé kan tí àwọn ènìyàn ń pín fídíò rẹ̀ kiri ti ṣẹlẹ̀, kìí se ilé ìjọsìn àwọn Kristẹni ní Nàìjíríà
FACT CHECK: Video of Ghanaian school fire incident falsely described as razed Nigerian church
RoundCheck to host poetry festival on media and information literacy on December 12
Ị́hé ńgósị́ ébé ńdị́ ụ́ká Naijiria jị́ égbè n’ụ́lọ́ ụ́ká ézị́ghị́ézị́
Hotunan da ke yawo na kiristocin Najeriya rike da makamai a coci suna yaudarar
Advertisement
Aa
TheCable Fact CheckTheCable Fact Check
Search
  • Home
  • Fact Check
  • Fake News
  • Check Am For Wazobia
Follow US

Wọn kò yin ìbọn pá ọmọkùnrin kan soso tí Wike bí ní orílẹ̀-èdè Amẹ́ríkà

Yemi Michael
By Yemi Michael Published March 9, 2023 2 Min Read
Share

Atẹjade/ìròyìn kan lórí ayélujára tí sọ wí pé wọn yin ìbọn pá ọmokùnrin kan soso tí Nyesom Wike, Gómìnà Ìpínlẹ̀ Rivers bí ní ìlú California, ní orílẹ̀-èdè Amẹ́ríkà. 

Atẹjade tí àwọn ènìyàn ń pín kiri náà sọ wí pé wọn pa ọmọ náà nítorí ipa tí bàbá rẹ̀ kó nínú ìbò Ààrẹ tí a se kọjá ní ọjọ́ Àbámẹ́ta (Satide) ni Nàìjíríà.

“ìfitónilétí ìròyìn tí ó sẹsẹ ṣẹlẹ̀: wọn yínbọn pa ọmọkùnrin kan soso tí Wike bí ní California, orílẹ̀-èdè Amẹ́ríkà nítorí ipa tí bàbá rẹ̀ kó nínú ìdìbò Ìpínlẹ̀ Rivers,” báyìí ni àkòrí ìkan nínú àwọn atẹjade náà wí.

“A fi yé wa pé ọmọkùnrin kan tí a kò dámọ̀ tí ó jẹ́ ọmọ ọdún méjìdínlógún ni ó yínbọn paá nítorí ipa tí bàbá rẹ̀ kó nínú ìdìbò Ìpínlẹ̀ Rivers.

Èsì ìwádìí tí a se kò ṣeé gbára lé. Èyí túmọ̀ sí pé ọ̀rọ̀ náà kìí se òótọ́/òtítọ́.

Ayẹwo tí ìwé ìròyìn TheCable se fi yé wa pé kò sí ìwé ìròyìn tí isẹ́ wọn dangajiya/tí ó ṣeé gbé ara lé tí ó sọ ọ̀rọ̀ tí ó ṣeé dimu nípa ọ̀rọ̀ yìí. Irọ́/ahesọ lásán-làsàn ni ọ̀rọ̀ yìí.

Àwọn tí ó gbé ìròyìn náà jáde lo àwòrán Wike pẹ̀lú ọmọkùnrin kan tí ó wọ aṣọ asekagba/ìparí ẹ̀kọ́ tí àwọn akẹ́kọ̀ọ́ máa ń wọ (gaun giraduesọn).

Ayẹwo àwòrán náà tí a se ní orí ayélujára fi yé wa pé àwòrán náà kọ́kọ́ jáde ní orí ayélujára nínú osù keje, ọdún 2022.

Jordan Nyesom-Wike, son of the Rivers State Governor, Nyesom Wike has graduated from the University of Exeter, in the United Kingdom… pls can u see why they are not talking about ASUU strike. Well Congratulations pic.twitter.com/tFvFnmmKpQ

— Odinala Ndi IGBO (@enyinnayaibeka) July 11, 2022

Gẹ́gẹ́bí àkòrí àwòrán náà tí ìwé ìròyìn The Nation gbé jáde, wọ́n ya àwòrán náà nígbà tí Gómìnà náà àti àwọn ẹbí rẹ̀ lọ sí ibi ajọyọ ìparí ẹ̀kọ́ ọmọ rẹ̀ ọkùnrin, ẹni tí àwọn oniroyin ofege/irọ́ ní orí ayélujára sọ wí pé wọn yinbọn pa ní orílẹ̀-èdè Amẹ́ríkà.

Nígbà tí o sọ ọ̀rọ̀ nípa atẹjade yìí, Kelvin Ebiri, ẹni tí ó jẹ́ oluranlọwọ fún àwọn ọ̀rọ̀ orí ayélujára fún Gómìnà Wike sọ wí pé ọ̀rọ̀ yìí kìí se òtítọ́. Irọ́ ńlá gbáà ni.

Please send your feedback, claims to fact check and corrections requests to [email protected]

Yemi Michael March 9, 2023 March 9, 2023
Share this Article
Facebook Twitter Email Copy Link Print
Leave a comment Leave a comment

Leave a Reply Cancel reply

Your email address will not be published. Required fields are marked *

POPULAR POSTS

Advertisement

Video wey tok sey Nigerian church dey on fire na lie, na Ghana school

One TikTok user claim sey jihadists burn church for di northern part of Nigeria. One…

December 12, 2025

Ị́hé ńgósị́ ụ́lọ́ákwụ́kwọ́ Ghana gbáráọ́kụ́ ká á sị́ n’ọ́bụ́ ụ́lọ́ ụ́ká dị́ nà Naijiria

Ótú onye na TikTok ekwuola na ndị jihad a gbaala ụlọ ụka ọkụ na mpaghara…

December 12, 2025

Bidiyon gobarar da ta faru a makarantar Ghana da aka bayyana karya a matsayin kona cocin Najeriya

Wani mai amfani da TikTok ya yi ikirarin cewa mayakan jihadi sun lalata wata Coci…

December 12, 2025

Ghana ni ìṣẹ̀lẹ iná ní ilé ìwé kan tí àwọn ènìyàn ń pín fídíò rẹ̀ kiri ti ṣẹlẹ̀, kìí se ilé ìjọsìn àwọn Kristẹni ní Nàìjíríà

Ẹnì kan tó ń lo TikTok, ibì kan lórí ayélujára tí áwọn ènìyàn ti máa…

December 12, 2025
Advertisement
Advertisement

YOU MAY ALSO LIKE

Video wey tok sey Nigerian church dey on fire na lie, na Ghana school

One TikTok user claim sey jihadists burn church for di northern part of Nigeria. One TikTok user — @WakaWakaplanet —…

CHECK AM FOR WAZOBIA
December 12, 2025

Ị́hé ńgósị́ ụ́lọ́ákwụ́kwọ́ Ghana gbáráọ́kụ́ ká á sị́ n’ọ́bụ́ ụ́lọ́ ụ́ká dị́ nà Naijiria

Ótú onye na TikTok ekwuola na ndị jihad a gbaala ụlọ ụka ọkụ na mpaghara ụ́gwụ́ nke Naịjiria. @WakaWakaplanet jiri…

CHECK AM FOR WAZOBIA
December 12, 2025

Bidiyon gobarar da ta faru a makarantar Ghana da aka bayyana karya a matsayin kona cocin Najeriya

Wani mai amfani da TikTok ya yi ikirarin cewa mayakan jihadi sun lalata wata Coci a yankin arewacin Najeriya. Wani…

CHECK AM FOR WAZOBIA
December 12, 2025

Ghana ni ìṣẹ̀lẹ iná ní ilé ìwé kan tí àwọn ènìyàn ń pín fídíò rẹ̀ kiri ti ṣẹlẹ̀, kìí se ilé ìjọsìn àwọn Kristẹni ní Nàìjíríà

Ẹnì kan tó ń lo TikTok, ibì kan lórí ayélujára tí áwọn ènìyàn ti máa ń fi àwòrán tàbí fídíò…

CHECK AM FOR WAZOBIA
December 12, 2025

CableCheck seeks to provide reliable tools and resources for readers to tackle the menace of fake and misleading materials constantly pushed into the public space from various sources. We monitor the accuracy of claims made in traditional and social media. We also provide a tracker to hold politicians and policymakers accountable for the plans and promises they make to the public. CableCheck is a project of the Cable Newspaper Journalism Foundation (CNJF), supported by the MacArthur Foundation and implemented by TheCable newspaper.

Follow US: 

LINKS

  • Contact
  • About Us
  • Non-Partisanship Policy
  • Funding
  • Correction Policy
© Copyright TheCable. All Rights reserved.
Welcome Back!

Sign in to your account

Lost your password?