TheCable Fact Check
  • Home
  • Fact Check
  • Fake News
  • Check Am For Wazobia
Reading: Ǹjẹ́ Nàìjíría ni àgbàrá ti gbé ọkọ̀ bọ̀gìnì yìí lọ?
Share
Latest News
Did Tinubu attend same school as Alexander Zingman? Here is what we know
FACT CHECK: No, Nigeria didn’t deploy peace support mission to Israel
FACT CHECK: Did lawmakers skip the national anthem during Tinubu’s Democracy Day speech?
FACT CHECK: Did a military coup oust Paul Biya as Cameroon’s president?
FACT CHECK: Ndume erred. 22 governors didn’t endorse Jonathan in 2015
Rárá, Pope Leo kò bẹ Tinubu kó tú Nnamdi Kanu sílẹ̀ ní àtìmọ́lé
Ḿbà, Pope Leo áyọghị Tinubu kà ọ́ tọ́pụ̀ Nnamdi Kanu nà ǹgá
No, Pope Leo no beg Tinubu to release Nnamdi Kanu
Advertisement
Aa
TheCable Fact CheckTheCable Fact Check
Search
  • Home
  • Fact Check
  • Fake News
  • Check Am For Wazobia
Follow US

Ǹjẹ́ Nàìjíría ni àgbàrá ti gbé ọkọ̀ bọ̀gìnì yìí lọ?

Elizabeth Ogunbamowo
By Elizabeth Ogunbamowo Published October 26, 2022 3 Min Read
Share

Dakore Egbuson-Akande, gbajúmọ̀ òṣèré tíátà Nollywood fi àwọn fọ́nrán kàn sí ojú òpó rẹ̀ lórí ìkànnì ibaraẹnisọrẹ (Instagram). Fọ́nrán náà ṣ’àfihàn ìjàmbá omiya’le, àgbàrá ya ṣọọbu tí ń da àwọn ènìyàn láàmú ni agbègbè Niger Delta orílẹ̀-èdè Nàìjíríà.

Dakore ní ontẹle tí ó pọ̀ tó mílíọ̀nù kan lé ní irínwó lórí oun àmúlò ìgbàlódé ayélujára náà.

Òṣèré obínrin náà fí fídíò mẹ́fà ọ̀tọ̀ọ̀tọ̀ sí ojú òpó rẹ̀ ni ọjọ́ àìkú, ìkan nínú àwọn fọ́nrán wọ̀nyí ṣ’àfihàn ọkọ̀ bọ̀gìnì funfun kan tí ó ń gbìyànjú láti kọjá sódì kejì nínú àgbàrá òjò.

Ṣùgbọ́n, ọkọ̀ náà há sí àárín ọ̀nà lẹ́yìn tí ẹkun omi fìí sí ẹ̀gbẹ kòtò kan. Lẹ́yìn o rẹyin, ọkọ̀ náà bọ́ sí inú kòtò botilẹjẹpe ọ̀pọ̀lọpọ̀ àwọn ènìyàn tó wà ní sàkání ìṣẹ̀lẹ̀ náà pariwo.

“A ti finá sórí òrùlé sùn!!! Ìṣẹ̀lẹ̀ abanilẹru lo ń ṣẹlẹ̀ ní ọ̀pọ̀lọpọ̀ agbègbè ni Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà, pàápàá ni Niger Delta, inú mi bajẹ fún orílẹ̀-èdè mi Nàìjíríà. Ni ìgbà wo ni àwọn olùdarí wa máa bẹ̀rẹ̀ sí ṣe ìtọ́jú àwọn ènìyàn?” Egbuson-Akande kọ èyí sí ojú òpó rẹ̀.

Àwọn aṣàmúlò ojú òpó bù ọwọ ìfẹ́ lú fọ́nrán ọkọ̀ bọ̀gìnì yìí ati àwọn fónrán márùn-ún tó s’àfihàn bí àgbàrá òjò se ṣọṣẹ ní àwọn agbègbè kan ní orílẹ̀-èdè Nàìjíríà, ni ìgbà ẹgbẹrun mẹ́fà àti ẹgbẹ̀rin dín ní mọ́kànlélógún (6,779). Kò sí àyè fún àwọn ènìyàn láti wo èsì fún ọ̀rọ̀ náà.

TheCable ṣe ìwádìí fídíò náà, èsì ìwádìí wà nì yìí:

Ifiidiododomulẹ

A se itọpinpin àwòrán àti ẹyin wa (reverse image search) lórí àwòrán tí a gba silẹ láti inú fọ́nrán àkọ́kọ́ yìí nípa lílo Labnol, ohun àmúlò ìgbàlódé tí a fi ń se ìwádìí oríṣun/ibi tí àwòrán àti àwọn mìíràn tó jọọ́ ti wá lórí ayélujára.

Àbájáde ìwádìí wa fihàn pé, fọ́nrán yìí ti wà lórí ayélujára láti ọdún 2017, àwọn olùmúlò sì ti lòó ní ọ̀pọ̀lọpọ̀ ìgbà, láti fi s’àfihàn ẹkun omi ní agbègbè míràn káàkiri àgbáyé. Kódà, wọ́n ti lo fọ́nrán náà fún Tropical Cyclone Dineo, èyí tí ó jẹ́ ìkan nínú afẹ́fẹ́ ìjì líle tó burú jùlọ tó ṣẹlẹ̀ ní iha ìwọ̀ oòrùn ti òkun orílẹ̀-èdè India (south-west Indian Ocean) àti agbede-méjì gúsù (southern hemisphere)

Ìwádìí ìwé ìròyìn TheCable fihàn pé wọ́n gbà fídíò náà silẹ ni Chaman ni ìlú Pakistan, ni ìgbà tí àgbàrá òjò bá ìlú náà fínra ni ọdún 2017.

Ní ìgbà tí a wo fídíò náà ni kíkún, a ríi wí pé àwọn ènìyàn tó n wòran nínú fídíò náà gbìyànjú láti ṣe iranlọwọ fún àwọn èrò inú ọkọ̀ náà.

Àbájáde ìwádìí: Wọn gba fọ́nrán yìí silẹ láti ọdún 2017 ni ìlú Pakistan, kìíse Nàìjíríà bí òṣèré tíátà yìí ti wí.

Please send your feedback, claims to fact check and corrections requests to [email protected]

Elizabeth Ogunbamowo December 13, 2023 October 26, 2022
Share this Article
Facebook Twitter Email Copy Link Print
Leave a comment Leave a comment

Leave a Reply Cancel reply

Your email address will not be published. Required fields are marked *

POPULAR POSTS

Advertisement

Did Tinubu attend same school as Alexander Zingman? Here is what we know

During the launch of the renewed hope mechanisation programme in Abuja on Monday, President Bola…

June 24, 2025

FACT CHECK: No, Nigeria didn’t deploy peace support mission to Israel

A Facebook video purports that Nigeria deployed troops for a joint peace support mission in…

June 24, 2025

FACT CHECK: Did lawmakers skip the national anthem during Tinubu’s Democracy Day speech?

A viral X post claims that Nigeria’s new national anthem was not recited during the…

June 13, 2025

FACT CHECK: Did a military coup oust Paul Biya as Cameroon’s president?

Reports of a military coup in Cameroon ousting President Paul Biya have gone viral on…

June 13, 2025
Advertisement
Advertisement

YOU MAY ALSO LIKE

Rárá, Pope Leo kò bẹ Tinubu kó tú Nnamdi Kanu sílẹ̀ ní àtìmọ́lé

Ẹni kan tí ó ń lo Facebook, ohun ìgbàlódé ibaraẹnisọrẹ orí ayélujára sọ pé Robert Francis Prevost, Pope Leo XIV…

CHECK AM FOR WAZOBIA
June 10, 2025

Ḿbà, Pope Leo áyọghị Tinubu kà ọ́ tọ́pụ̀ Nnamdi Kanu nà ǹgá

Ótù onye na Facebook ekwuola na Pope Leo na ụfọdụ ndị Bishop yọrọ onye isiala Bola Tinubu ka ọ tọpụ…

CHECK AM FOR WAZOBIA
June 10, 2025

No, Pope Leo no beg Tinubu to release Nnamdi Kanu

One Facebook user claim sey Pope Leo XVI and oda bishops join mouth beg President Bola Tinubu to release Nnamdi…

CHECK AM FOR WAZOBIA
June 10, 2025

A’a, Paparoma Leo bai nemi Tinubu ya saki Nnamdi Kanu ba

Wani mai amfani da Facebook ya yi ikirarin cewa Paparoma Leo na 16 da wasu limaman coci sun roki shugaban…

CHECK AM FOR WAZOBIA
June 10, 2025

CableCheck seeks to provide reliable tools and resources for readers to tackle the menace of fake and misleading materials constantly pushed into the public space from various sources. We monitor the accuracy of claims made in traditional and social media. We also provide a tracker to hold politicians and policymakers accountable for the plans and promises they make to the public. CableCheck is a project of the Cable Newspaper Journalism Foundation (CNJF), supported by the MacArthur Foundation and implemented by TheCable newspaper.

Follow US: 

LINKS

  • Contact
  • About Us
  • Non-Partisanship Policy
  • Funding
  • Correction Policy
© Copyright TheCable. All Rights reserved.
Welcome Back!

Sign in to your account

Lost your password?