TheCable Fact Check
  • Home
  • Fact Check
  • Fake News
  • Check Am For Wazobia
Reading: Ṣé Sanusi ló kọ àtẹ̀jáde lórí ọ̀rọ̀ Atiku, Tinubu àti Obi?
Share
Latest News
Rárá, Nàìjíríà kò fi àwọn ọmọ iṣẹ́ ológun rán sẹ sí Ísírẹ́lì láti dá rògbòdìyàn tó ń ṣẹlẹ̀ níbẹ̀ dúró
Ḿbà, Naijiria ézipụ̀ghị̀ ńdị́ ágha ńkwàdó ùdó nà òbòdò Isreal
No, Nigeria no send peace support mission go Israel
A’a, Najeriya ba ta tura tawagar taimakon zaman lafiya zuwa Isra’ila ba
Ǹjẹ́ Tinubu àti Alexander Zingman lọ sí ilé-ìwé kan náà? Èyí ni ohun tí a mọ̀
Tinubu nà Alexander Zingman ọ̀ gàrà ótù ụ́lọ̀ákwụ́kwọ́? Lèé íhé ányị́ mà
Tinubu go di same school wit Alexander Zingman? Na wetin we sabi be dis
Shin Tinubu ya halarci makaranta daya da Alexander Zingman? Ga abin da muka sani
Advertisement
Aa
TheCable Fact CheckTheCable Fact Check
Search
  • Home
  • Fact Check
  • Fake News
  • Check Am For Wazobia
Follow US

Ṣé Sanusi ló kọ àtẹ̀jáde lórí ọ̀rọ̀ Atiku, Tinubu àti Obi?

Elizabeth Ogunbamowo
By Elizabeth Ogunbamowo Published June 22, 2022 4 Min Read
Share

Àtẹ̀jade kan tí ó ṣàlàyé ìdí tí àwọn olùdíje ipò ààrẹ mẹtẹta wọnyi fi jáde fún ìdíje naa, ni àwọn ènìyàn ń pín káàkiri orí ẹ̀rọ ayélujára.

 

Àtẹ̀jáde yìí, tí wọn ni Sanusi Lamido Sanusi, ẹni tíí ṣe ọ̀gá àgbà tẹ́lẹ̀ ri ile ifowopamo apapọ ni Naijiria, kọ, daba pé àwọn olùdíje yìí kò sí nínú ìdíje náà torí owó.

 

“Oun kàn pàtàkì nípa àwọn mẹtẹta yíì tí wọn du ipò ààrẹ, ni wípé, ọ̀kọ̀ọ̀kan ninu won ò ṣeé nítorí owó,” ìpínrọ àkọ́kọ́ nínú àtẹ̀jáde náà wí.

Àtẹ̀jáde yìí gbé àhesọ pé Atiku Abubakar, olùdíje ipò ààrẹ ní ẹgbẹ́ òṣèlú alatako Peoples Democratic Party (PDP), ti kó owó jẹ ‘dáadáa’, ó kàn fẹ́ wá dáhùn àkọlé ‘ààrẹ’ lọ́nàkọnà ni.

Àhesọ míràn wípé Bola Tinubu, olùdíje ipò ààrẹ ní ẹgbẹ́ òṣèlú All Progressives Congress (APC), kàn fẹ́ mú ibarajẹjẹ rẹ̀ ṣẹ ni.

“Ní òpin ọjọ́, yóò kọ́wa oun tó túmọ̀sí láti jẹ oníwà ìbàjẹ́ paraku,” àtẹ̀jáde náà wí.

Nípa Peter Obi, olùdíje ipò ààrẹ Labour Party, àtẹ̀jáde náà sọ wípé gómìnà Ipinle Anambra teleri náà jẹ́ ènìyàn tó ní itẹlọrun, tí ó sí fẹ́ gba orilẹ èdè Nàìjíríà sílẹ̀ lọ́wọ́ àjálù burúkú, tí ó bá dé ipò ààrẹ l’ọdún 2023.

Àtẹ̀jáde yìí, tí o bẹ̀rẹ̀ sí ní k’àlè k’áko láti ọjọ́ kọkàndínlógún oṣù kẹfà, ni àwọn olùmúlò ojú òpó ìbánidọ́rẹ̀ẹ́ Facebook àti ìkànnì abẹ́yẹfò Twitter sàtúpín lọ́pọ̀lọpọ̀ ìgbà.

Ní ọjọ́ kọkàndínlógún oṣù kẹfà, ojú òpó ìbánidọ́rẹ̀ẹ́ Facebook kan ló sàtúpín àtẹ̀jáde yì. Ojú òpó yìí tí ń jẹ́ CeleSylv Updates ní òntẹ̀lẹ́ ọ̀kẹ́ mẹ̀ta àbọ̀. Àwọn olùmúlò sí tí sàtúpín àtẹ̀jáde náà ní ọ̀nà ẹgbẹrun mẹta, wọn sí tí bu ọwọ́ ìfẹ́ lu ní ìgbà ẹgbẹ̀sán pẹ̀lú ọ̀rọ̀ ìwòye eedegbeje lekan.

Olùmúlò ìkànnì abẹ́yẹfò kan, Fame Kid, fi àtẹ̀jáde yìí si ojú òpó rẹ̀ ní ago méjì àbọ òkú ìṣẹjú kan, lọ́jọ́ náà, àwọn olùmúlò míràn sàtúpín rẹ lọ́nà eedegbeje o lekan, wọ́n sì bu ọwọ́ ìfẹ́ lú ní ọ̀pọ̀ ìgbà.

Today being #June19 Sanusi the former CBN Governor describes the three Presidential candidates in his own word 👇👇#WorldSickleCellDay #ASUU kirikiri Obi's VP Consent Ruger Ckay Rufai Airtel #PeterObiForPresident2023 pic.twitter.com/ahXne7OZA5

— FÄMËKīīD🇳🇬⚕️ (@famekiid_) June 19, 2022

Max Vayshia, olùmúlò míràn, tó fi àhesọ yìí si ojú òpó rẹ̀, ti ní àtupín lọ̀nà ẹ̀ta-dín-ní-ojì dín ní ẹ̀ẹ́dẹ́gbẹ́rún (873), wọ́n sì ti bù ọwọ́ ìfẹ́ lu ní ìgbà ẹ̀ẹ́dẹ́gbẹ́je (1,300), ó sì tún ní ẹ̀ta dín ní ọgọ́ta, ọ̀rọ̀ ìwòye.

Listen, there has been NO better description of the 3 Presidential aspirants than this. I promise you, you won't be getting a better description of Peter Obi, Jagaban and Atiku. Sanusi is SPOT ON on this. READ👇🏾 pic.twitter.com/ILLUu34otH

— Maxvayshia™ (@maxvayshia) June 19, 2022

 

I just saw this flying around, Have you read the way Mohammad Sanusi described the three presidential candidates!
Atiku | tinubu | Peter Obi

I can see some comments online backlashing the post. Whichever way the post is 100% truth.

It is left for us to make our own decisions. pic.twitter.com/0C9TY0xbYG

— Hauwa (@hauwaladisanusi) June 19, 2022

https://twitter.com/austine_okpegwa/status/1538592999638171653?s=20&t=lPfxJsrkWrdQIcHcMU-5Uw

 

Ọ̀pọ̀lọpọ̀ aṣàmúlò ojú òpó ìkànnì yìí lọ gba ìròyìn náà gbọ́, èyí tí ó hàn gbangba nínú àwọn ọ̀rọ̀ ìwòye tí wọn ti n gboriyin fún ònkòwé fún ìtú sí wẹ̀wẹ̀ ọ̀rọ̀ náà.

Iṣamudaju

Àyẹwò TheCable lórí ayélujára fihàn pé kòsí ilé iṣẹ ìròyìn tótó gbẹ́kẹ̀lẹ́ kan-kan tó gbé ìròyìn yìí.

 

Ní ìgbà tí TheCable kàn sí Sanusi, ó sọ pé àtẹ̀jáde náà kò wá láti ọ̀dọ̀ oun. “Òfègè ni àtẹ̀jáde yìí, kìí ṣe ọwọ́ mi ló ti wá,” Sanusi sọ fún TheCable.

 

Àbájáde Ìwádì

Ẹ̀tàn jẹ lásán ni àtẹ̀jáde tí ó ṣ’àyẹ̀wò oun amóríyà fún àwọn olùdíje ipò ààrẹ mẹtẹta wọnyi. Sanusi Lamido Sanusi kọ́ ló kọọ́.

 

A kọ ìròyìn yìí ni àjọṣepọ̀ pẹ̀lú Report for the World, ètò àgbáyé tí ń ṣe àtìlẹ́yìn iṣẹ́ ìròyìn tiwa-n-tiwa.

 

TAGGED: cbn, Election 2023, peter obi, sanusi lamido sanusi, Tinubu

Please send your feedback, claims to fact check and corrections requests to [email protected]

Elizabeth Ogunbamowo June 22, 2022 June 22, 2022
Share this Article
Facebook Twitter Email Copy Link Print
Leave a comment Leave a comment

Leave a Reply Cancel reply

Your email address will not be published. Required fields are marked *

POPULAR POSTS

Advertisement

Rárá, Nàìjíríà kò fi àwọn ọmọ iṣẹ́ ológun rán sẹ sí Ísírẹ́lì láti dá rògbòdìyàn tó ń ṣẹlẹ̀ níbẹ̀ dúró

Ìròyìn lati inú fídíò Facebook kan sọ pé Nàìjíríà fi àwọn ọmọ ogun ránṣẹ́ sí…

June 28, 2025

Ḿbà, Naijiria ézipụ̀ghị̀ ńdị́ ágha ńkwàdó ùdó nà òbòdò Isreal

Ótù ihe ngosị si na Facebook kwuru na Naijiria zipụrụ ndị agha ka ha gaa…

June 28, 2025

No, Nigeria no send peace support mission go Israel

One Facebook video claim sey Nigeria send soldiers go Israel for joint peace support mission.…

June 28, 2025

A’a, Najeriya ba ta tura tawagar taimakon zaman lafiya zuwa Isra’ila ba

Wani faifan bidiyo na Facebook ya nuna cewa Najeriya ta tura dakaru domin aikin hadin…

June 28, 2025
Advertisement
Advertisement

YOU MAY ALSO LIKE

Rárá, Nàìjíríà kò fi àwọn ọmọ iṣẹ́ ológun rán sẹ sí Ísírẹ́lì láti dá rògbòdìyàn tó ń ṣẹlẹ̀ níbẹ̀ dúró

Ìròyìn lati inú fídíò Facebook kan sọ pé Nàìjíríà fi àwọn ọmọ ogun ránṣẹ́ sí orílẹ̀ èdè Ísírẹ́lì kí rògbòdìyàn…

CHECK AM FOR WAZOBIA
June 28, 2025

Ḿbà, Naijiria ézipụ̀ghị̀ ńdị́ ágha ńkwàdó ùdó nà òbòdò Isreal

Ótù ihe ngosị si na Facebook kwuru na Naijiria zipụrụ ndị agha ka ha gaa kwàdó udo na mba Isreal.…

CHECK AM FOR WAZOBIA
June 28, 2025

No, Nigeria no send peace support mission go Israel

One Facebook video claim sey Nigeria send soldiers go Israel for joint peace support mission. One male broadcaster wey dey…

CHECK AM FOR WAZOBIA
June 28, 2025

A’a, Najeriya ba ta tura tawagar taimakon zaman lafiya zuwa Isra’ila ba

Wani faifan bidiyo na Facebook ya nuna cewa Najeriya ta tura dakaru domin aikin hadin gwiwa na tallafawa zaman lafiya…

CHECK AM FOR WAZOBIA
June 28, 2025

CableCheck seeks to provide reliable tools and resources for readers to tackle the menace of fake and misleading materials constantly pushed into the public space from various sources. We monitor the accuracy of claims made in traditional and social media. We also provide a tracker to hold politicians and policymakers accountable for the plans and promises they make to the public. CableCheck is a project of the Cable Newspaper Journalism Foundation (CNJF), supported by the MacArthur Foundation and implemented by TheCable newspaper.

Follow US: 

LINKS

  • Contact
  • About Us
  • Non-Partisanship Policy
  • Funding
  • Correction Policy
© Copyright TheCable. All Rights reserved.
Welcome Back!

Sign in to your account

Lost your password?