TheCable Fact Check
  • Home
  • Fact Check
  • Fake News
  • Check Am For Wazobia
Reading: Ṣé Lawan kọ ẹgbẹ́ òṣèlú APC sílè fún ẹgbẹ́ alatako PDP?
Share
Latest News
Ókwú Badenoch nà ụ́mụ̀ yá ápụ̀ghị̀ ínwétá íkíké ị́bụ ńdị́ Naijiria bụ̀ àsị́
Kemi Badenoch claim sey her children no fit get Nigerian citizenship but she no tok true
Irọ́ ni Kemi Badenoch pa pé òfin kò fààyè gba àwọn ọmọ òhun láti di ọmọ Nàìjíríà
Maganar Kemi Badenoch na cewa ‘ya’yanta ba za su iya samun shaidar zama dan Najeriya ba karya ne
FACT CHECK: Kemi Badenoch’s claim that her children can’t get Nigerian citizenship is false
Naijiria ọ̀ kàgbùrù ńkwékọ́rị́tá àzụ́máhị́á àkụ̀ ọ̀nàtàràchí yá nà US nwèrè n’íhì ḿmáchí visa?
Ǹjẹ́ Nàìjíríà dá àjọṣe lórí àwọn àlùmọ́ọ́nì láàárín òhun àti Amẹ́ríkà dúró nítorí visa?
Nigeria stop ‘mineral deal’ with US afta visa restriction?
Advertisement
Aa
TheCable Fact CheckTheCable Fact Check
Search
  • Home
  • Fact Check
  • Fake News
  • Check Am For Wazobia
Follow US

Ṣé Lawan kọ ẹgbẹ́ òṣèlú APC sílè fún ẹgbẹ́ alatako PDP?

Elizabeth Ogunbamowo
By Elizabeth Ogunbamowo Published June 22, 2022 4 Min Read
Share

Ní ọjọ́ ketàdínlogun oṣù kẹfà, ìròyìn tàn ràn-ìn lórí ìkànnì abẹ́yẹfò Twitter pé ààrẹ ilè ìgbìmọ̀ aṣòfin apapo, Ahmad Lawani kúrò ní ẹgbẹ́ òṣèlú rẹ̀.

Àwọn àtẹ̀jáde kan lórí ìkànnì náà wi pe  ààrẹ ilé ìgbìmọ̀ aṣòfin náà ti fi ẹgbẹ́ òṣèlú All Progressives Party (APC) sílẹ̀, ó sí tí darapọ̀ mọ́ ẹgbẹ́ òṣèlú alatako, Peoples Democratic Party (PDP).

“Ahmad Lawan ti kúrò ní ẹgbẹ́ òṣèlú APC, o sì ti darapọ̀ mọ́ PDP torí pé o fẹ ṣetọju ibujoko rẹ̀ ni Ile igbimo asofin   apapo, kìíṣe pé ó fẹ́ sin awọn ènìyàn tó wà lábẹ́ ìṣàkóso ìjọba agbegbe rẹ̀. Ẹ̀kọ́ àkọ́kọ́: àpò arawọn ní wọ́n lé,” báyìí ni èyán kan ti orúkọ rẹ̀ ń jẹ Mustapha kọ sí ojú òpó ìkànnì abẹ́yẹfò rẹ.

Àtẹ̀jáde yìí ti ní, ókéré jù, atunpin ní ọnà egbeje le ni ogoji ati mejo, àwọn olumulo oju opo naa ti iye won je egberun ni ona merin ati eedegbeta o le mejo sí tí bù ọwọ ìfẹ́ lu.

Ojú òpó kan tó gbé àmì àṣẹ ìkànnì Twitter, @GoldmyneTV náà gbé àhesọ ọ̀rọ̀ naa pe  Lawan ti kọ ẹgbẹ́ òṣèlú APC sílè. Ojú òpó yìí ní òntẹ̀lẹ́ ọ̀kẹ́ méjì ààbò (50,000), ó sí ma ń sàtúpín àwọn ìròyìn nípa eré ìdárayá.

 

Bí ọ̀rọ̀ náà ṣe rí 

Alága ẹgbẹ́ APC, Abdullahi Adamu ti kọ́kọ́ sọ pé Lawan ni olùdíje àjùmọ̀yàn ẹgbẹ́ náà.

Àbálọ àbábọ̀, Lawan kópa nínú ìdíje náà, tí ó sí gbé ipò kẹrin pẹ̀lú ìbò éjì lé ní àádọ̀jọ.

Ààrẹ ilè ìgbìmọ̀ aṣòfin náà kùnà níbi ìdìbò abẹ́nú náà, èyí tí Bola Tinubu, gómìnà tẹ́lẹ̀ rí ìpínlè Èkó ti jáwé olubori pẹlu ìbò egbefa ati aadorin o lekan .

Iṣamudaju

Ní àsìkò tí ìròyìn yìí n tán ràn-ìn lórí ìkànnì abẹ́yẹfò Twitter yìí, àyẹwò TheCable fihàn pé kò sí ilé iṣẹ́ ìròyìn tó ṣe gbẹ́kẹ̀lé tó gbé ìròyìn náà.

Nínú àtẹ̀jáde kan ní ọjọ́ àbámẹ́ta, Ọlá Awoniyi, agbẹnusọ ààrẹ ilè ìgbìmọ̀ aṣòfin náà sọ wípé ìròyìn òfégè ní àhesọ naa pe Lawan kúrò ní ẹgbẹ́ òṣèlú APC.

Ṣáájú nínú ọ̀sẹ̀ yìí, ààrẹ ilè ìgbìmọ̀ aṣòfin ti kéde pé àwọn aṣòfin méjì láti ìpínlè Kebbi ti fi ẹgbẹ́ òṣèlú náà sílẹ̀.

Yahaya Abdullahi, aṣoju s’ofin Kebbi North, ati Adamu Aliero, aṣoju s’ofin Kebbi Central, fi ìwé ranṣẹ pe won ti fi ẹgbẹ́ òṣèlú APC sílẹ̀, wọ́n sì ti darapọ̀ mọ ẹgbẹ́ òṣèlú PDP.

“Fídíò kan tó ṣàfihàn ibi ti ààrẹ ilẹ̀ ìgbìmọ̀ aṣòfin ti ń ka lẹ́tà ti Aliero fi rànṣẹ̀ ní àwọn èèyàn kàn ṣe ayédèrú rẹ láti jẹ́ kí àwọn ènìyàn rò pé Lawani ti kọ ẹgbẹ́ òṣèlú APC sílẹ̀,” Awoniyi ni o wi bayi.

Ó ṣàlàyé pé ojúlówó fídíò jẹ́ ìsẹ́jú mẹ̀ta, àti ìṣẹ́jú aaya ọgbọ̀n, fihàn pé Lawan ka lẹta Aliero, tí ó fi to  àwọn akẹgbẹ́ rẹ leti   pe òun ti kúrò lẹgbẹ òṣèlú kan sí omiran. Fídíò yìí ní àwọn kan gé kúrú si ìṣẹ́ju-aaya mẹ́rìndínlọ́gbọ̀n.

Ẹ̀yà fídíò tí wọ́n tí ṣatunkọ rẹ yìí ni wọ́n ti fi tan àwọn ará ìlú.

 

Àbájáde ìwádì

Àhesọ ọ̀rọ̀ nipe ààrẹ ilé ìgbìmọ̀ aṣòfin Ahmad Lawan ti kọ ẹgbẹ́ òṣèlú APC sílẹ̀ fún ẹgbẹ́ alatako PDP. Iro gbàá ni èyí.

 

A kọ ìròyìn yìí ni ajọṣepọ pẹlu Report for the World, eto agbaye ti o ṣe atilẹyin iṣẹ iroyin tiwa-n-tiwa.

TAGGED: Ahmad Lawan, APC, Elections 2023., PDP

Please send your feedback, claims to fact check and corrections requests to [email protected]

Elizabeth Ogunbamowo June 22, 2022 June 22, 2022
Share this Article
Facebook Twitter Email Copy Link Print
Leave a comment Leave a comment

Leave a Reply Cancel reply

Your email address will not be published. Required fields are marked *

POPULAR POSTS

Advertisement

Ókwú Badenoch nà ụ́mụ̀ yá ápụ̀ghị̀ ínwétá íkíké ị́bụ ńdị́ Naijiria bụ̀ àsị́

Kemi Badenoch, onye ndú òtù Conservative Party nke obodo United Kingdom, ekwuola na ọ gaghị…

July 22, 2025

Kemi Badenoch claim sey her children no fit get Nigerian citizenship but she no tok true

Kemi Badenoch, leader of di United Kingdom Conservative Party, claim sey she no fit pass…

July 22, 2025

Irọ́ ni Kemi Badenoch pa pé òfin kò fààyè gba àwọn ọmọ òhun láti di ọmọ Nàìjíríà

Kemi Badenoch, arábìnrin tó jẹ́ olórí ẹgbẹ́ òsèlú alátakò tí wọ́n ń pè ní Conservative…

July 22, 2025

Maganar Kemi Badenoch na cewa ‘ya’yanta ba za su iya samun shaidar zama dan Najeriya ba karya ne

Kemi Badenoch, shugabar jam'iyyar masu ra'ayin rikau ta Burtaniya, ta yi ikirarin cewa ba za…

July 22, 2025
Advertisement
Advertisement

YOU MAY ALSO LIKE

Ókwú Badenoch nà ụ́mụ̀ yá ápụ̀ghị̀ ínwétá íkíké ị́bụ ńdị́ Naijiria bụ̀ àsị́

Kemi Badenoch, onye ndú òtù Conservative Party nke obodo United Kingdom, ekwuola na ọ gaghị enyenwu ụmụ ya ikike ịbụ…

CHECK AM FOR WAZOBIA
July 22, 2025

Kemi Badenoch claim sey her children no fit get Nigerian citizenship but she no tok true

Kemi Badenoch, leader of di United Kingdom Conservative Party, claim sey she no fit pass her right of Nigerian citizenship…

CHECK AM FOR WAZOBIA
July 22, 2025

Irọ́ ni Kemi Badenoch pa pé òfin kò fààyè gba àwọn ọmọ òhun láti di ọmọ Nàìjíríà

Kemi Badenoch, arábìnrin tó jẹ́ olórí ẹgbẹ́ òsèlú alátakò tí wọ́n ń pè ní Conservative Party ní orílẹ̀ èdè United…

CHECK AM FOR WAZOBIA
July 22, 2025

Maganar Kemi Badenoch na cewa ‘ya’yanta ba za su iya samun shaidar zama dan Najeriya ba karya ne

Kemi Badenoch, shugabar jam'iyyar masu ra'ayin rikau ta Burtaniya, ta yi ikirarin cewa ba za ta iya mika hakkinta na…

CHECK AM FOR WAZOBIA
July 22, 2025

CableCheck seeks to provide reliable tools and resources for readers to tackle the menace of fake and misleading materials constantly pushed into the public space from various sources. We monitor the accuracy of claims made in traditional and social media. We also provide a tracker to hold politicians and policymakers accountable for the plans and promises they make to the public. CableCheck is a project of the Cable Newspaper Journalism Foundation (CNJF), supported by the MacArthur Foundation and implemented by TheCable newspaper.

Follow US: 

LINKS

  • Contact
  • About Us
  • Non-Partisanship Policy
  • Funding
  • Correction Policy
© Copyright TheCable. All Rights reserved.
Welcome Back!

Sign in to your account

Lost your password?