TheCable Fact Check
  • Home
  • Fact Check
  • Fake News
  • Check Am For Wazobia
Reading: Ǹjẹ́ òtítọ́ ni pé Ìpínlẹ̀ Nasarawa kò tíì yá owó láti ìgbà tí Tinubu ti di ààrẹ?
Share
Latest News
FACT CHECK: Viral image depicting ‘Obasanjo prostrating for Ladoja’ photoshopped
Wike tụ̀rụ̀ àsị́. Peter Obi mèrè ńtụ̀líáká ọ̀chị́chị́ ḿpághárá m̀gbè ọ́ bụ̀ gọ́vánọ̀ Anambra
Irọ́ ni Wike pa. Peter Obi ṣètò ìdìbò ìjọba ìbílẹ̀ nígbà tí ó jẹ́ gómìnà Ìpínlẹ̀ Anambra
Wike yayi kuskure. Peter Obi ya gudanar da zaben LG a matsayin gwamnan Anambra
Wike make mistake. Peter Obi conduct LG election as Anambra governor
Video wey show as Thomas Partey dey blame ‘rape’ case on racism na fake
Bidiyon da ke nuna Partey yana zargin shari’ar ‘fyade’ akan wariyar launin fata da aka gyara ta hanyar lambobi
AI ni fídíò tí ó fi ẹ̀sùn ìbánifipálòpọ̀ kan Thomas Partey
Advertisement
Aa
TheCable Fact CheckTheCable Fact Check
Search
  • Home
  • Fact Check
  • Fake News
  • Check Am For Wazobia
Follow US

Ǹjẹ́ òtítọ́ ni pé Ìpínlẹ̀ Nasarawa kò tíì yá owó láti ìgbà tí Tinubu ti di ààrẹ?

Yemi Michael
By Yemi Michael Published December 10, 2024 4 Min Read
Share

Ní ọjọ́ Ajé, Abdullahi Sule, gómìnà Ìpínlẹ̀ Nasarawa sọ pé Ìpínlẹ̀ òhun kò yá owó kankan láti ìgbà tí Bọlá Tinubu ti di aàrẹ Nàìjíríà.

Sule sọ ọ̀rọ̀ yìí nígbà tí ó se ìpàdé pẹ̀lú àwọn ara Ìpínlẹ̀ Nasarawa, èyí tí ilé isẹ amohunmaworan tí a mọ̀ sí Channels Television ṣe agbekalẹ rẹ̀.

“Mo gbọ pé ẹni kan sọ pé láti ìgbà tí Ààrẹ Tinubu tí di olórí, owó tí ó ń wọlé sí àpò àwọn Ìpínlẹ̀ ti lé síi, àwọn sì fẹ́ mọ ohun tí wọ́n ń fi àwọn owó yìí ṣe,” gómìnà yìí ló sọ báyìí.

“Ẹ lọ sí àwọn àwọn Ìpínlẹ̀, ẹ máa rí àwọn nǹkan tí àwọn gómìnà ń fi àwọn owó yìí se.

“Ní Ìpínlẹ̀ Nasarawa, n kò tí ì yá owó kankan láti ìgbà tí Tinubu ti di Ààrẹ, mo sì lè fọwọ́ sọ̀yà pé a ní ilẹ̀ bíi ẹgbẹ̀rún mẹwa hẹkita tí a fi ń ṣe àgbẹ̀. A sì ti san gbogbo àwọn ohun tí a ń lò, mo lè máa sọrọ síwájú síi.

AYẸWO 

Àwọn ọmọ Nàìjíríà fi ìbò yàn Tinubu gẹ́gẹ́bí Ààrẹ ní oṣù kejì, ọdún 2023, wọ́n sì búra fún un ní ọjọ́ kọkàndínlógún, oṣù karùn-ún, ọdún 2023.

Láti lè se àyẹ̀wò ọ̀rọ̀ yìí, TheCable, ìwé ìròyìn orí ayélujára ṣàyẹ̀wò gbèsè owó tí àwọn Ìpínlẹ̀ jẹ àwọn ayanilowo ní Nàìjíríà àti àwọn orílẹ̀ èdè mìíràn lórí ohun ayélujára tí Debt Management Office (DMO) se agbekalẹ rẹ̀ láti ìgbà tí Tinubu ti di Ààrẹ sí àsìkò yìí.

GBÈSÈ OWÓ TÍ NASARAWA JẸ 

Ní oṣù kẹfà, ọdún 2023, oṣù kan lẹ́hìn ìgbà tí Tinubu di Ààrẹ, DMO sọ pé gbèsè owó tí Nasarawa jẹ́ àwọn ayanilowo ní Nàìjíríà jẹ́ biliọnu mọkanlelaadọrin ó lé ní ọ̀pọ̀lọpọ̀ mílíọ̀nù naira.

Nasarawa’s domestic debt as of June 2023

Ní oṣù kẹfà, ọdún 2024, gbèsè yìí lọ silẹ, ó di biliọnu mẹtalelogun àti ẹẹdẹgbẹrun ó lé ogójì miliọnu náírà. Èyí túmọ̀ sí pé ìdá ọgọ́ta àti bíi mẹ́fà ni gbèsè Nasarawa fi lọ silẹ sí ìyè gbèsè ìgbà tí Tinubu di Ààrẹ.

Nasarawa’s domestic debt as of June 2024

GBÈSÈ OWÓ TÍ NASARAWA JẸ ÀWỌN AYANILOWO NÍ ÀWỌN ORÍLẸ̀ ÈDÈ MÌÍRÀN

Nígbà tí TheCable se àyẹ̀wò ṣíwájú nípa gbèsè tí Nasarawa jẹ, a ríi pé gbèsè náà ti di mílíọ̀nù mejilelaaadọta ó lé  pupọ ni owó dọ́là ní oṣù kẹfà, ọdún 2023.

Nasarawa’s external debt as of June 2023

Nígbà tí a tún se àyẹ̀wò ṣíwájú síi, a ríi pé iye tí gbèsè yìí jẹ́ ní oṣù kẹfà, ọdún 2024 ju iye ti ó jẹ́ ní oṣù kẹfà, ọdún 2023.

Nasarawa’s external debt as of June 2024

BÍ A SE RÍ Ọ̀RỌ̀ YÌÍ ṢÍ

Ọ̀rọ̀ tí Sule sọ pé ìjọba òhun kò yá owó láti ìgbà tí Tinubu ti di Ààrẹ kìí se irọ.

TAGGED: Abdullahi Sule, debt, Fact Check, Fact check in Yoruba, Nasarawa state, News in Yorùbá

Please send your feedback, claims to fact check and corrections requests to [email protected]

Yemi Michael December 23, 2024 December 10, 2024
Share this Article
Facebook Twitter Email Copy Link Print
Leave a comment Leave a comment

Leave a Reply Cancel reply

Your email address will not be published. Required fields are marked *

POPULAR POSTS

Advertisement

FACT CHECK: Viral image depicting ‘Obasanjo prostrating for Ladoja’ photoshopped

An image showing a person prostrating for Rashidi Ladoja, the Olubadan-in-waiting and former governor of…

July 11, 2025

Wike tụ̀rụ̀ àsị́. Peter Obi mèrè ńtụ̀líáká ọ̀chị́chị́ ḿpághárá m̀gbè ọ́ bụ̀ gọ́vánọ̀ Anambra

Nyesom Wike, onye minista nke isi obodo Naijiria bụ FCT, kwuru na Peter Obi, onye…

July 11, 2025

Irọ́ ni Wike pa. Peter Obi ṣètò ìdìbò ìjọba ìbílẹ̀ nígbà tí ó jẹ́ gómìnà Ìpínlẹ̀ Anambra

Nyesom Wike, minisita fún Federal Capital Territory (FCT), Abuja, olú ìlú orílẹ̀ èdè Nàìjíríà, sọ…

July 11, 2025

Wike yayi kuskure. Peter Obi ya gudanar da zaben LG a matsayin gwamnan Anambra

Nyesom Wike, ministan babban birnin tarayya Abuja, ya ce Peter Obi, tsohon gwamnan Anambra kuma…

July 11, 2025
Advertisement
Advertisement

YOU MAY ALSO LIKE

Wike tụ̀rụ̀ àsị́. Peter Obi mèrè ńtụ̀líáká ọ̀chị́chị́ ḿpághárá m̀gbè ọ́ bụ̀ gọ́vánọ̀ Anambra

Nyesom Wike, onye minista nke isi obodo Naijiria bụ FCT, kwuru na Peter Obi, onye bụ buru gọvanọ Anambra steetị…

CHECK AM FOR WAZOBIA
July 11, 2025

Irọ́ ni Wike pa. Peter Obi ṣètò ìdìbò ìjọba ìbílẹ̀ nígbà tí ó jẹ́ gómìnà Ìpínlẹ̀ Anambra

Nyesom Wike, minisita fún Federal Capital Territory (FCT), Abuja, olú ìlú orílẹ̀ èdè Nàìjíríà, sọ pé Peter Obi, ẹni tí…

CHECK AM FOR WAZOBIA
July 11, 2025

Wike yayi kuskure. Peter Obi ya gudanar da zaben LG a matsayin gwamnan Anambra

Nyesom Wike, ministan babban birnin tarayya Abuja, ya ce Peter Obi, tsohon gwamnan Anambra kuma dan takarar shugaban kasa na…

CHECK AM FOR WAZOBIA
July 11, 2025

Wike make mistake. Peter Obi conduct LG election as Anambra governor

Nyesom Wike, minister of di Federal Capital Territory (FCT), tok sey Peter Obi, forma govnor of Anambra and 2023 Labour…

CHECK AM FOR WAZOBIA
July 11, 2025

CableCheck seeks to provide reliable tools and resources for readers to tackle the menace of fake and misleading materials constantly pushed into the public space from various sources. We monitor the accuracy of claims made in traditional and social media. We also provide a tracker to hold politicians and policymakers accountable for the plans and promises they make to the public. CableCheck is a project of the Cable Newspaper Journalism Foundation (CNJF), supported by the MacArthur Foundation and implemented by TheCable newspaper.

Follow US: 

LINKS

  • Contact
  • About Us
  • Non-Partisanship Policy
  • Funding
  • Correction Policy
© Copyright TheCable. All Rights reserved.
Welcome Back!

Sign in to your account

Lost your password?