TheCable Fact Check
  • Home
  • Fact Check
  • Fake News
  • Check Am For Wazobia
Reading: Ǹjẹ́ òtítọ́ ni pé Ìpínlẹ̀ Nasarawa kò tíì yá owó láti ìgbà tí Tinubu ti di ààrẹ?
Share
Latest News
FACT CHECK: Did lawmakers skip the national anthem during Tinubu’s Democracy Day speech?
FACT CHECK: Did a military coup oust Paul Biya as Cameroon’s president?
FACT CHECK: Ndume erred. 22 governors didn’t endorse Jonathan in 2015
Rárá, Pope Leo kò bẹ Tinubu kó tú Nnamdi Kanu sílẹ̀ ní àtìmọ́lé
Ḿbà, Pope Leo áyọghị Tinubu kà ọ́ tọ́pụ̀ Nnamdi Kanu nà ǹgá
No, Pope Leo no beg Tinubu to release Nnamdi Kanu
A’a, Paparoma Leo bai nemi Tinubu ya saki Nnamdi Kanu ba
FACT CHECK: No, Pope Leo didn’t ask Tinubu to release Nnamdi Kanu
Advertisement
Aa
TheCable Fact CheckTheCable Fact Check
Search
  • Home
  • Fact Check
  • Fake News
  • Check Am For Wazobia
Follow US

Ǹjẹ́ òtítọ́ ni pé Ìpínlẹ̀ Nasarawa kò tíì yá owó láti ìgbà tí Tinubu ti di ààrẹ?

Yemi Michael
By Yemi Michael Published December 10, 2024 4 Min Read
Share

Ní ọjọ́ Ajé, Abdullahi Sule, gómìnà Ìpínlẹ̀ Nasarawa sọ pé Ìpínlẹ̀ òhun kò yá owó kankan láti ìgbà tí Bọlá Tinubu ti di aàrẹ Nàìjíríà.

Sule sọ ọ̀rọ̀ yìí nígbà tí ó se ìpàdé pẹ̀lú àwọn ara Ìpínlẹ̀ Nasarawa, èyí tí ilé isẹ amohunmaworan tí a mọ̀ sí Channels Television ṣe agbekalẹ rẹ̀.

“Mo gbọ pé ẹni kan sọ pé láti ìgbà tí Ààrẹ Tinubu tí di olórí, owó tí ó ń wọlé sí àpò àwọn Ìpínlẹ̀ ti lé síi, àwọn sì fẹ́ mọ ohun tí wọ́n ń fi àwọn owó yìí ṣe,” gómìnà yìí ló sọ báyìí.

“Ẹ lọ sí àwọn àwọn Ìpínlẹ̀, ẹ máa rí àwọn nǹkan tí àwọn gómìnà ń fi àwọn owó yìí se.

“Ní Ìpínlẹ̀ Nasarawa, n kò tí ì yá owó kankan láti ìgbà tí Tinubu ti di Ààrẹ, mo sì lè fọwọ́ sọ̀yà pé a ní ilẹ̀ bíi ẹgbẹ̀rún mẹwa hẹkita tí a fi ń ṣe àgbẹ̀. A sì ti san gbogbo àwọn ohun tí a ń lò, mo lè máa sọrọ síwájú síi.

AYẸWO 

Àwọn ọmọ Nàìjíríà fi ìbò yàn Tinubu gẹ́gẹ́bí Ààrẹ ní oṣù kejì, ọdún 2023, wọ́n sì búra fún un ní ọjọ́ kọkàndínlógún, oṣù karùn-ún, ọdún 2023.

Láti lè se àyẹ̀wò ọ̀rọ̀ yìí, TheCable, ìwé ìròyìn orí ayélujára ṣàyẹ̀wò gbèsè owó tí àwọn Ìpínlẹ̀ jẹ àwọn ayanilowo ní Nàìjíríà àti àwọn orílẹ̀ èdè mìíràn lórí ohun ayélujára tí Debt Management Office (DMO) se agbekalẹ rẹ̀ láti ìgbà tí Tinubu ti di Ààrẹ sí àsìkò yìí.

GBÈSÈ OWÓ TÍ NASARAWA JẸ 

Ní oṣù kẹfà, ọdún 2023, oṣù kan lẹ́hìn ìgbà tí Tinubu di Ààrẹ, DMO sọ pé gbèsè owó tí Nasarawa jẹ́ àwọn ayanilowo ní Nàìjíríà jẹ́ biliọnu mọkanlelaadọrin ó lé ní ọ̀pọ̀lọpọ̀ mílíọ̀nù naira.

Nasarawa’s domestic debt as of June 2023

Ní oṣù kẹfà, ọdún 2024, gbèsè yìí lọ silẹ, ó di biliọnu mẹtalelogun àti ẹẹdẹgbẹrun ó lé ogójì miliọnu náírà. Èyí túmọ̀ sí pé ìdá ọgọ́ta àti bíi mẹ́fà ni gbèsè Nasarawa fi lọ silẹ sí ìyè gbèsè ìgbà tí Tinubu di Ààrẹ.

Nasarawa’s domestic debt as of June 2024

GBÈSÈ OWÓ TÍ NASARAWA JẸ ÀWỌN AYANILOWO NÍ ÀWỌN ORÍLẸ̀ ÈDÈ MÌÍRÀN

Nígbà tí TheCable se àyẹ̀wò ṣíwájú nípa gbèsè tí Nasarawa jẹ, a ríi pé gbèsè náà ti di mílíọ̀nù mejilelaaadọta ó lé  pupọ ni owó dọ́là ní oṣù kẹfà, ọdún 2023.

Nasarawa’s external debt as of June 2023

Nígbà tí a tún se àyẹ̀wò ṣíwájú síi, a ríi pé iye tí gbèsè yìí jẹ́ ní oṣù kẹfà, ọdún 2024 ju iye ti ó jẹ́ ní oṣù kẹfà, ọdún 2023.

Nasarawa’s external debt as of June 2024

BÍ A SE RÍ Ọ̀RỌ̀ YÌÍ ṢÍ

Ọ̀rọ̀ tí Sule sọ pé ìjọba òhun kò yá owó láti ìgbà tí Tinubu ti di Ààrẹ kìí se irọ.

TAGGED: Abdullahi Sule, debt, Fact Check, Fact check in Yoruba, Nasarawa state, News in Yorùbá

Please send your feedback, claims to fact check and corrections requests to [email protected]

Yemi Michael December 23, 2024 December 10, 2024
Share this Article
Facebook Twitter Email Copy Link Print
Leave a comment Leave a comment

Leave a Reply Cancel reply

Your email address will not be published. Required fields are marked *

POPULAR POSTS

Advertisement

FACT CHECK: Did lawmakers skip the national anthem during Tinubu’s Democracy Day speech?

A viral X post claims that Nigeria’s new national anthem was not recited during the…

June 13, 2025

FACT CHECK: Did a military coup oust Paul Biya as Cameroon’s president?

Reports of a military coup in Cameroon ousting President Paul Biya have gone viral on…

June 13, 2025

FACT CHECK: Ndume erred. 22 governors didn’t endorse Jonathan in 2015

On June 8, Ali Ndume, senator representing Borno south, claimed that 22 governors elected on…

June 10, 2025

Rárá, Pope Leo kò bẹ Tinubu kó tú Nnamdi Kanu sílẹ̀ ní àtìmọ́lé

Ẹni kan tí ó ń lo Facebook, ohun ìgbàlódé ibaraẹnisọrẹ orí ayélujára sọ pé Robert…

June 10, 2025
Advertisement
Advertisement

YOU MAY ALSO LIKE

FACT CHECK: Did lawmakers skip the national anthem during Tinubu’s Democracy Day speech?

A viral X post claims that Nigeria’s new national anthem was not recited during the Democracy Day event at the…

Fact CheckTop Stories
June 13, 2025

Rárá, Pope Leo kò bẹ Tinubu kó tú Nnamdi Kanu sílẹ̀ ní àtìmọ́lé

Ẹni kan tí ó ń lo Facebook, ohun ìgbàlódé ibaraẹnisọrẹ orí ayélujára sọ pé Robert Francis Prevost, Pope Leo XIV…

CHECK AM FOR WAZOBIA
June 10, 2025

Ḿbà, Pope Leo áyọghị Tinubu kà ọ́ tọ́pụ̀ Nnamdi Kanu nà ǹgá

Ótù onye na Facebook ekwuola na Pope Leo na ụfọdụ ndị Bishop yọrọ onye isiala Bola Tinubu ka ọ tọpụ…

CHECK AM FOR WAZOBIA
June 10, 2025

No, Pope Leo no beg Tinubu to release Nnamdi Kanu

One Facebook user claim sey Pope Leo XVI and oda bishops join mouth beg President Bola Tinubu to release Nnamdi…

CHECK AM FOR WAZOBIA
June 10, 2025

CableCheck seeks to provide reliable tools and resources for readers to tackle the menace of fake and misleading materials constantly pushed into the public space from various sources. We monitor the accuracy of claims made in traditional and social media. We also provide a tracker to hold politicians and policymakers accountable for the plans and promises they make to the public. CableCheck is a project of the Cable Newspaper Journalism Foundation (CNJF), supported by the MacArthur Foundation and implemented by TheCable newspaper.

Follow US: 

LINKS

  • Contact
  • About Us
  • Non-Partisanship Policy
  • Funding
  • Correction Policy
© Copyright TheCable. All Rights reserved.
Welcome Back!

Sign in to your account

Lost your password?