TheCable Fact Check
  • Home
  • Fact Check
  • Fake News
  • Check Am For Wazobia
Reading: Ṣé Sanusi ló kọ àtẹ̀jáde lórí ọ̀rọ̀ Atiku, Tinubu àti Obi?
Share
Latest News
FACT CHECK: Video showing ‘bridge collapsing in Nasarawa’ is AI-generated
MISINFO ALERT: Viral video of ‘foreign arms dealer’ in Zamfara is from 2021, says army
Ókwú Badenoch nà ụ́mụ̀ yá ápụ̀ghị̀ ínwétá íkíké ị́bụ ńdị́ Naijiria bụ̀ àsị́
Kemi Badenoch claim sey her children no fit get Nigerian citizenship but she no tok true
Irọ́ ni Kemi Badenoch pa pé òfin kò fààyè gba àwọn ọmọ òhun láti di ọmọ Nàìjíríà
Maganar Kemi Badenoch na cewa ‘ya’yanta ba za su iya samun shaidar zama dan Najeriya ba karya ne
FACT CHECK: Kemi Badenoch’s claim that her children can’t get Nigerian citizenship is false
Naijiria ọ̀ kàgbùrù ńkwékọ́rị́tá àzụ́máhị́á àkụ̀ ọ̀nàtàràchí yá nà US nwèrè n’íhì ḿmáchí visa?
Advertisement
Aa
TheCable Fact CheckTheCable Fact Check
Search
  • Home
  • Fact Check
  • Fake News
  • Check Am For Wazobia
Follow US

Ṣé Sanusi ló kọ àtẹ̀jáde lórí ọ̀rọ̀ Atiku, Tinubu àti Obi?

Elizabeth Ogunbamowo
By Elizabeth Ogunbamowo Published June 22, 2022 4 Min Read
Share

Àtẹ̀jade kan tí ó ṣàlàyé ìdí tí àwọn olùdíje ipò ààrẹ mẹtẹta wọnyi fi jáde fún ìdíje naa, ni àwọn ènìyàn ń pín káàkiri orí ẹ̀rọ ayélujára.

 

Àtẹ̀jáde yìí, tí wọn ni Sanusi Lamido Sanusi, ẹni tíí ṣe ọ̀gá àgbà tẹ́lẹ̀ ri ile ifowopamo apapọ ni Naijiria, kọ, daba pé àwọn olùdíje yìí kò sí nínú ìdíje náà torí owó.

 

“Oun kàn pàtàkì nípa àwọn mẹtẹta yíì tí wọn du ipò ààrẹ, ni wípé, ọ̀kọ̀ọ̀kan ninu won ò ṣeé nítorí owó,” ìpínrọ àkọ́kọ́ nínú àtẹ̀jáde náà wí.

Àtẹ̀jáde yìí gbé àhesọ pé Atiku Abubakar, olùdíje ipò ààrẹ ní ẹgbẹ́ òṣèlú alatako Peoples Democratic Party (PDP), ti kó owó jẹ ‘dáadáa’, ó kàn fẹ́ wá dáhùn àkọlé ‘ààrẹ’ lọ́nàkọnà ni.

Àhesọ míràn wípé Bola Tinubu, olùdíje ipò ààrẹ ní ẹgbẹ́ òṣèlú All Progressives Congress (APC), kàn fẹ́ mú ibarajẹjẹ rẹ̀ ṣẹ ni.

“Ní òpin ọjọ́, yóò kọ́wa oun tó túmọ̀sí láti jẹ oníwà ìbàjẹ́ paraku,” àtẹ̀jáde náà wí.

Nípa Peter Obi, olùdíje ipò ààrẹ Labour Party, àtẹ̀jáde náà sọ wípé gómìnà Ipinle Anambra teleri náà jẹ́ ènìyàn tó ní itẹlọrun, tí ó sí fẹ́ gba orilẹ èdè Nàìjíríà sílẹ̀ lọ́wọ́ àjálù burúkú, tí ó bá dé ipò ààrẹ l’ọdún 2023.

Àtẹ̀jáde yìí, tí o bẹ̀rẹ̀ sí ní k’àlè k’áko láti ọjọ́ kọkàndínlógún oṣù kẹfà, ni àwọn olùmúlò ojú òpó ìbánidọ́rẹ̀ẹ́ Facebook àti ìkànnì abẹ́yẹfò Twitter sàtúpín lọ́pọ̀lọpọ̀ ìgbà.

Ní ọjọ́ kọkàndínlógún oṣù kẹfà, ojú òpó ìbánidọ́rẹ̀ẹ́ Facebook kan ló sàtúpín àtẹ̀jáde yì. Ojú òpó yìí tí ń jẹ́ CeleSylv Updates ní òntẹ̀lẹ́ ọ̀kẹ́ mẹ̀ta àbọ̀. Àwọn olùmúlò sí tí sàtúpín àtẹ̀jáde náà ní ọ̀nà ẹgbẹrun mẹta, wọn sí tí bu ọwọ́ ìfẹ́ lu ní ìgbà ẹgbẹ̀sán pẹ̀lú ọ̀rọ̀ ìwòye eedegbeje lekan.

Olùmúlò ìkànnì abẹ́yẹfò kan, Fame Kid, fi àtẹ̀jáde yìí si ojú òpó rẹ̀ ní ago méjì àbọ òkú ìṣẹjú kan, lọ́jọ́ náà, àwọn olùmúlò míràn sàtúpín rẹ lọ́nà eedegbeje o lekan, wọ́n sì bu ọwọ́ ìfẹ́ lú ní ọ̀pọ̀ ìgbà.

Today being #June19 Sanusi the former CBN Governor describes the three Presidential candidates in his own word 👇👇#WorldSickleCellDay #ASUU kirikiri Obi's VP Consent Ruger Ckay Rufai Airtel #PeterObiForPresident2023 pic.twitter.com/ahXne7OZA5

— FÄMËKīīD🇳🇬⚕️ (@famekiid_) June 19, 2022

Max Vayshia, olùmúlò míràn, tó fi àhesọ yìí si ojú òpó rẹ̀, ti ní àtupín lọ̀nà ẹ̀ta-dín-ní-ojì dín ní ẹ̀ẹ́dẹ́gbẹ́rún (873), wọ́n sì ti bù ọwọ́ ìfẹ́ lu ní ìgbà ẹ̀ẹ́dẹ́gbẹ́je (1,300), ó sì tún ní ẹ̀ta dín ní ọgọ́ta, ọ̀rọ̀ ìwòye.

Listen, there has been NO better description of the 3 Presidential aspirants than this. I promise you, you won't be getting a better description of Peter Obi, Jagaban and Atiku. Sanusi is SPOT ON on this. READ👇🏾 pic.twitter.com/ILLUu34otH

— Maxvayshia™ (@maxvayshia) June 19, 2022

 

I just saw this flying around, Have you read the way Mohammad Sanusi described the three presidential candidates!
Atiku | tinubu | Peter Obi

I can see some comments online backlashing the post. Whichever way the post is 100% truth.

It is left for us to make our own decisions. pic.twitter.com/0C9TY0xbYG

— Hauwa (@hauwaladisanusi) June 19, 2022

https://twitter.com/austine_okpegwa/status/1538592999638171653?s=20&t=lPfxJsrkWrdQIcHcMU-5Uw

 

Ọ̀pọ̀lọpọ̀ aṣàmúlò ojú òpó ìkànnì yìí lọ gba ìròyìn náà gbọ́, èyí tí ó hàn gbangba nínú àwọn ọ̀rọ̀ ìwòye tí wọn ti n gboriyin fún ònkòwé fún ìtú sí wẹ̀wẹ̀ ọ̀rọ̀ náà.

Iṣamudaju

Àyẹwò TheCable lórí ayélujára fihàn pé kòsí ilé iṣẹ ìròyìn tótó gbẹ́kẹ̀lẹ́ kan-kan tó gbé ìròyìn yìí.

 

Ní ìgbà tí TheCable kàn sí Sanusi, ó sọ pé àtẹ̀jáde náà kò wá láti ọ̀dọ̀ oun. “Òfègè ni àtẹ̀jáde yìí, kìí ṣe ọwọ́ mi ló ti wá,” Sanusi sọ fún TheCable.

 

Àbájáde Ìwádì

Ẹ̀tàn jẹ lásán ni àtẹ̀jáde tí ó ṣ’àyẹ̀wò oun amóríyà fún àwọn olùdíje ipò ààrẹ mẹtẹta wọnyi. Sanusi Lamido Sanusi kọ́ ló kọọ́.

 

A kọ ìròyìn yìí ni àjọṣepọ̀ pẹ̀lú Report for the World, ètò àgbáyé tí ń ṣe àtìlẹ́yìn iṣẹ́ ìròyìn tiwa-n-tiwa.

 

TAGGED: cbn, Election 2023, peter obi, sanusi lamido sanusi, Tinubu

Please send your feedback, claims to fact check and corrections requests to [email protected]

Elizabeth Ogunbamowo June 22, 2022 June 22, 2022
Share this Article
Facebook Twitter Email Copy Link Print
Leave a comment Leave a comment

Leave a Reply Cancel reply

Your email address will not be published. Required fields are marked *

POPULAR POSTS

Advertisement

FACT CHECK: Video showing ‘bridge collapsing in Nasarawa’ is AI-generated

A video showing a bridge collapse incident is circulating across social media platforms, especially on…

July 24, 2025

MISINFO ALERT: Viral video of ‘foreign arms dealer’ in Zamfara is from 2021, says army

The Nigerian Army says a viral video claiming the arrest of a foreign arms dealer…

July 24, 2025

Ókwú Badenoch nà ụ́mụ̀ yá ápụ̀ghị̀ ínwétá íkíké ị́bụ ńdị́ Naijiria bụ̀ àsị́

Kemi Badenoch, onye ndú òtù Conservative Party nke obodo United Kingdom, ekwuola na ọ gaghị…

July 22, 2025

Kemi Badenoch claim sey her children no fit get Nigerian citizenship but she no tok true

Kemi Badenoch, leader of di United Kingdom Conservative Party, claim sey she no fit pass…

July 22, 2025
Advertisement
Advertisement

YOU MAY ALSO LIKE

Ókwú Badenoch nà ụ́mụ̀ yá ápụ̀ghị̀ ínwétá íkíké ị́bụ ńdị́ Naijiria bụ̀ àsị́

Kemi Badenoch, onye ndú òtù Conservative Party nke obodo United Kingdom, ekwuola na ọ gaghị enyenwu ụmụ ya ikike ịbụ…

CHECK AM FOR WAZOBIA
July 22, 2025

Kemi Badenoch claim sey her children no fit get Nigerian citizenship but she no tok true

Kemi Badenoch, leader of di United Kingdom Conservative Party, claim sey she no fit pass her right of Nigerian citizenship…

CHECK AM FOR WAZOBIA
July 22, 2025

Irọ́ ni Kemi Badenoch pa pé òfin kò fààyè gba àwọn ọmọ òhun láti di ọmọ Nàìjíríà

Kemi Badenoch, arábìnrin tó jẹ́ olórí ẹgbẹ́ òsèlú alátakò tí wọ́n ń pè ní Conservative Party ní orílẹ̀ èdè United…

CHECK AM FOR WAZOBIA
July 22, 2025

Maganar Kemi Badenoch na cewa ‘ya’yanta ba za su iya samun shaidar zama dan Najeriya ba karya ne

Kemi Badenoch, shugabar jam'iyyar masu ra'ayin rikau ta Burtaniya, ta yi ikirarin cewa ba za ta iya mika hakkinta na…

CHECK AM FOR WAZOBIA
July 22, 2025

CableCheck seeks to provide reliable tools and resources for readers to tackle the menace of fake and misleading materials constantly pushed into the public space from various sources. We monitor the accuracy of claims made in traditional and social media. We also provide a tracker to hold politicians and policymakers accountable for the plans and promises they make to the public. CableCheck is a project of the Cable Newspaper Journalism Foundation (CNJF), supported by the MacArthur Foundation and implemented by TheCable newspaper.

Follow US: 

LINKS

  • Contact
  • About Us
  • Non-Partisanship Policy
  • Funding
  • Correction Policy
© Copyright TheCable. All Rights reserved.
Welcome Back!

Sign in to your account

Lost your password?