TheCable Fact Check
  • Home
  • Fact Check
  • Fake News
  • Check Am For Wazobia
Reading: Ǹjẹ́ ìmọ̀ ẹ̀rọ ibaraẹnisọrọ jẹ́ ohun tó ń mówó wọlé púpọ̀ fún Nàìjíríà láti ọdún 2021?
Share
Latest News
Video wey tok sey Nigerian church dey on fire na lie, na Ghana school
Ị́hé ńgósị́ ụ́lọ́ákwụ́kwọ́ Ghana gbáráọ́kụ́ ká á sị́ n’ọ́bụ́ ụ́lọ́ ụ́ká dị́ nà Naijiria
Bidiyon gobarar da ta faru a makarantar Ghana da aka bayyana karya a matsayin kona cocin Najeriya
Ghana ni ìṣẹ̀lẹ iná ní ilé ìwé kan tí àwọn ènìyàn ń pín fídíò rẹ̀ kiri ti ṣẹlẹ̀, kìí se ilé ìjọsìn àwọn Kristẹni ní Nàìjíríà
FACT CHECK: Video of Ghanaian school fire incident falsely described as razed Nigerian church
RoundCheck to host poetry festival on media and information literacy on December 12
Ị́hé ńgósị́ ébé ńdị́ ụ́ká Naijiria jị́ égbè n’ụ́lọ́ ụ́ká ézị́ghị́ézị́
Hotunan da ke yawo na kiristocin Najeriya rike da makamai a coci suna yaudarar
Advertisement
Aa
TheCable Fact CheckTheCable Fact Check
Search
  • Home
  • Fact Check
  • Fake News
  • Check Am For Wazobia
Follow US

Ǹjẹ́ ìmọ̀ ẹ̀rọ ibaraẹnisọrọ jẹ́ ohun tó ń mówó wọlé púpọ̀ fún Nàìjíríà láti ọdún 2021?

Yemi Michael
By Yemi Michael Published February 2, 2025 5 Min Read
Share

Vincent Olatunji, ìkan lára àwọn ọga Nigeria Data Protection Commission (NDPC) sọ pé ìmọ̀ ẹ̀rọ ibaraẹnisọrọ jẹ́ ara àwọn ìkan pàtàkì tó ń mú owó tó gbé pẹẹli wọlé fún orílẹ̀ èdè Nàìjíríà láti ọdún 2021, owó yìí sì tó ìdá mẹrindinlogun sí ìdá méjìdínlógún gbogbo owó tí ó wọlé fún Nàìjíríà láti bíi ọdún mẹrin sí márùn-ún sẹhin.

Arákùnrin yìí sọ ọ̀rọ̀ yìí ní ọjọ́rú, nígbà tí wọ́n ń fi ọ̀rọ̀ wáa lẹ́nu wò lórí ètò kan tí wọ́n ń pè ní the Prime Time Programme lórí tẹlifisọn tí a mọ̀ sí Arise Television.

“Ní ọdún mẹrin tàbí márùn-ún sẹhin, ìmọ̀ ẹ̀rọ ibaraẹnisọrọ jẹ́ ohun tí ó mú owó tó pọ̀ jù lọ wọlé fún orílẹ̀ èdè Nàìjíríà, èyí tí ó wà láàárín ìdá mẹrindinlogun sí méjìdínlógún,” Olatunji ló sọ báyìí.

“Ohun tí a ń lé, ní bíi ọdún díẹ̀ sí ìgbà yìí, tí a bá ń wo triliọnu kan dọ́là ọ̀rọ̀ ajé tí Ààrẹ Bọla Tinubu fẹ́ jẹ́ kí ó máa wọlé fún Nàìjíríà, ni bí kí ohun ìmọ̀ ẹ̀rọ àti sayẹnsi máa mú owó bíi idà ogún wọlé lára gbogbo owó tí ó ń wọlé fún Nàìjíríà.

“Tí àwọn adarí àwọn ohun mìíràn bá ní ètò tó dára tí wọ́n ń mú owó wọlé fún Nàìjíríà, Nàìjíríà yóò dára síi.

AYẸWO Ọ̀RỌ̀ YÌÍ TÍ THECABLE NEWSPAPER SE RÈÉ

CableCheck se àyẹ̀wò àwọn ọ̀rọ̀ tí National Bureau of Statistics (NBS), ẹ̀ka ìjọba tí ó máa ń rí sí ohun tí a lè fi mọ bí ìdàgbàsókè se rí fi síta ní ọdún 2021 sí bíi oṣù keje sí oṣù kẹsàn-án, ọdún 2024.

Ọ̀rọ̀ yìí fi ye wa pé ní ọdún 2021, iṣẹ́ àgbẹ̀/ọ̀gbìn ló mú owó wọlé fún Nàìjíríà jù. Iye owó tí iṣẹ́ yìí mú wọlé fún Nàìjíríà jẹ́ ìdá bíi mẹrindinlọgbọn gbogbo owó tí ó wọlé fún Nàìjíríà. Ìdá owó tí káràkátà mú wọlé jẹ́ ìdá bíi mẹrindinlogun, owó tí ohun ìmọ̀ ẹ̀rọ tí ó máa ń mú nnkan ṣíṣe yà mú wọlé jẹ́ ìdá mẹrindinlogun.

Ní ọdún 2022, owó tí iṣẹ́ àgbẹ̀ mú wọlé kò dín sí ìdá tó mú wọlé ní ọdún tí a mẹ́nubà lókè.

Ní ọdún 2023, isẹ àgbẹ̀ mú owó ìdá bíi marunlelogun àti díẹ̀ wọlé, ohun ìmọ̀ ẹ̀rọ mú ìdá owó bíi mẹtadinlogun àti díẹ̀ wọlé, káràkátà sì mú ìdá bíi mẹrindinlogun wọlé.

NBS kò tíì fi iye owó tí àwọn nǹkan yìí àti àwọn mìíràn mú wọlé ní ọdún 2024 síta. Àmọ́sá, a rí idà owó tí àwọn nǹkan yìí mú wọlé láàárín oṣù Kínní sí oṣù kẹta, ọdún 2024.

Láàárín oṣù kìíní sí oṣù kẹta, ọdún 2024, a ríi pé ìdá mọkanlelogun àti díẹ̀ ni owó tí iṣẹ́ àgbẹ̀ mú wọlé, iye tí ìmọ̀ ẹ̀rọ mú wọlé jẹ́ ìdá bíi méjìdínlógún, káràkátà sì mú ìdá bíi mẹrindinlogun wọlé.

Ní àárín oṣù kẹrin sí oṣù kẹfà, ọdún 2024, ìdá bíi mẹtalelogun ni iṣẹ́ àgbẹ̀ mú wọlé, ìmọ̀ ẹ̀rọ mú ìdá mọkandinlogun wọlé, káràkátà sì mú ìdá mẹrindinlogun àti díẹ̀ wọlé.

Ní àárín oṣù keje sí oṣù kẹsàn-án, ọdún 2024, iṣẹ́ àgbẹ̀ mú ìdá mejidinlọgbọn wọlé, ohun ìmọ̀ ẹ̀rọ mú ìdá bíi mẹtadinlogun wọlé, káràkátà sì mú ìdá bíi mẹẹdogun wọlé.

BÍ A SE RÍ Ọ̀RỌ̀ YÌÍ ṢÍ

Bí a bá wo àwọn ìdá owó tí a mẹ́nubà yìí, a máa ríi pé irọ́ ni ọ̀rọ̀ tí ẹnì yìí sọ pé ohun ìmọ̀ ẹ̀rọ ni ó mú owó tí ìdá rẹ̀ pọ̀ jù wọlé fún Nàìjíríà léraléra ní ọdún mẹrin sẹhin.

Isẹ àgbẹ̀ ni ó mú owó tó jù wọlé fún Nàìjíríà ní àwọn ọdún tí a ṣàyẹ̀wò wọ́n yìí.

TAGGED: Fact Check, Fact check in Yoruba, GDP, ICT, News in Yorùbá

Please send your feedback, claims to fact check and corrections requests to [email protected]

Yemi Michael February 2, 2025 February 2, 2025
Share this Article
Facebook Twitter Email Copy Link Print
Leave a comment Leave a comment

Leave a Reply Cancel reply

Your email address will not be published. Required fields are marked *

POPULAR POSTS

Advertisement

Video wey tok sey Nigerian church dey on fire na lie, na Ghana school

One TikTok user claim sey jihadists burn church for di northern part of Nigeria. One…

December 12, 2025

Ị́hé ńgósị́ ụ́lọ́ákwụ́kwọ́ Ghana gbáráọ́kụ́ ká á sị́ n’ọ́bụ́ ụ́lọ́ ụ́ká dị́ nà Naijiria

Ótú onye na TikTok ekwuola na ndị jihad a gbaala ụlọ ụka ọkụ na mpaghara…

December 12, 2025

Bidiyon gobarar da ta faru a makarantar Ghana da aka bayyana karya a matsayin kona cocin Najeriya

Wani mai amfani da TikTok ya yi ikirarin cewa mayakan jihadi sun lalata wata Coci…

December 12, 2025

Ghana ni ìṣẹ̀lẹ iná ní ilé ìwé kan tí àwọn ènìyàn ń pín fídíò rẹ̀ kiri ti ṣẹlẹ̀, kìí se ilé ìjọsìn àwọn Kristẹni ní Nàìjíríà

Ẹnì kan tó ń lo TikTok, ibì kan lórí ayélujára tí áwọn ènìyàn ti máa…

December 12, 2025
Advertisement
Advertisement

YOU MAY ALSO LIKE

Video wey tok sey Nigerian church dey on fire na lie, na Ghana school

One TikTok user claim sey jihadists burn church for di northern part of Nigeria. One TikTok user — @WakaWakaplanet —…

CHECK AM FOR WAZOBIA
December 12, 2025

Ị́hé ńgósị́ ụ́lọ́ákwụ́kwọ́ Ghana gbáráọ́kụ́ ká á sị́ n’ọ́bụ́ ụ́lọ́ ụ́ká dị́ nà Naijiria

Ótú onye na TikTok ekwuola na ndị jihad a gbaala ụlọ ụka ọkụ na mpaghara ụ́gwụ́ nke Naịjiria. @WakaWakaplanet jiri…

CHECK AM FOR WAZOBIA
December 12, 2025

Bidiyon gobarar da ta faru a makarantar Ghana da aka bayyana karya a matsayin kona cocin Najeriya

Wani mai amfani da TikTok ya yi ikirarin cewa mayakan jihadi sun lalata wata Coci a yankin arewacin Najeriya. Wani…

CHECK AM FOR WAZOBIA
December 12, 2025

Ghana ni ìṣẹ̀lẹ iná ní ilé ìwé kan tí àwọn ènìyàn ń pín fídíò rẹ̀ kiri ti ṣẹlẹ̀, kìí se ilé ìjọsìn àwọn Kristẹni ní Nàìjíríà

Ẹnì kan tó ń lo TikTok, ibì kan lórí ayélujára tí áwọn ènìyàn ti máa ń fi àwòrán tàbí fídíò…

CHECK AM FOR WAZOBIA
December 12, 2025

CableCheck seeks to provide reliable tools and resources for readers to tackle the menace of fake and misleading materials constantly pushed into the public space from various sources. We monitor the accuracy of claims made in traditional and social media. We also provide a tracker to hold politicians and policymakers accountable for the plans and promises they make to the public. CableCheck is a project of the Cable Newspaper Journalism Foundation (CNJF), supported by the MacArthur Foundation and implemented by TheCable newspaper.

Follow US: 

LINKS

  • Contact
  • About Us
  • Non-Partisanship Policy
  • Funding
  • Correction Policy
© Copyright TheCable. All Rights reserved.
Welcome Back!

Sign in to your account

Lost your password?